< Ndari 19 >

1 Jehova akĩĩra Musa na Harũni atĩrĩ,
Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni pé,
2 “Ũndũ ũyũ nĩ wa kũrũmĩrĩrwo thĩinĩ wa watho ũrĩa Jehova aathanĩte: Ĩra andũ a Isiraeli makũrehere moori ndune ĩtarĩ kaũũgũ kana kameni, na ĩtarĩ yekĩrwo icooki.
“Èyí ni ohun tí òfin Olúwa pàṣẹ béèrè lọ́wọ́ yín. Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli, kí wọn mú ẹgbọrọ ọ̀dọ́ màlúù pupa tí kò lábùkù tàbí àbàwọ́n, lára èyí tí a kò tí ì di àjàgà mọ́.
3 Mũmĩnengere Eleazaru, ũrĩa mũthĩnjĩri-Ngai; ĩtwarwo nja ya kambĩ, na ĩthĩnjĩrwo hau mbere yake.
Ẹ mú fún Eleasari àlùfáà, yóò sì mu jáde lọ sí ẹ̀yìn ibùdó kí ó sì pa á ní ojú rẹ.
4 Nake Eleazaru, ũcio mũthĩnjĩri-Ngai, oe thakame na kĩara gĩake, na amĩminjaminje maita mũgwanja amĩroretie na mwena wa mbere wa Hema-ya Gũtũnganwo.
Nígbà náà ni Eleasari àlùfáà yóò mú lára ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sórí ìka ọwọ́ rẹ̀ yóò sì wọn lẹ́ẹ̀méje ní ọ̀kánkán iwájú àgọ́ ìpàdé.
5 Nayo moori ĩyo ĩcinwo yothe akĩonaga, ũguo nĩ kuuga rũũa rwayo, na nyama, na thakame, o na taatha wayo.
Ní ojú rẹ̀ ni àlùfáà yóò ti sun ọ̀dọ́ abo màlúù yìí: awọ ara rẹ̀, ẹ̀jẹ̀ rẹ̀, ẹran-ara àti ìgbẹ́ rẹ̀.
6 Mũthĩnjĩri-Ngai ũcio oe rũkũ rwa mũtarakwa, na mũthobi, na guoya wa rangi wa gakarakũ, aciikie igũrũ wa moori ĩyo ĩrahĩa.
Àlùfáà yóò mú igi kedari, hísópù àti òwú òdòdó yóò sì jù wọ́n sí àárín ọ̀dọ́ abo màlúù tí a ń sun.
7 Thuutha wa ũguo mũthĩnjĩri-Ngai ũcio no nginya athambie nguo ciake na ethambe mwĩrĩ na maaĩ. Thuutha ũcio no acooke kambĩ, no arĩ na thaahu o nginya hwaĩ-inĩ.
Lẹ́yìn náà, àlùfáà gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, kí ó sì wẹ ara rẹ̀ pẹ̀lú omi lẹ́yìn náà ó lè wá sínú àgọ́. Ṣùgbọ́n yóò jẹ́ aláìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́.
8 Mũndũ ũrĩa ũrĩcinaga moori ĩyo no nginya athambie nguo ciake na ethambe mwĩrĩ na maaĩ, na o nake atiinde arĩ na thaahu nginya hwaĩ-inĩ.
Ẹni tí ó sun ún náà gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀ kí ó sì wẹ̀ pẹ̀lú omi, òun náà yóò jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
9 “Mũndũ ũtarĩ na thaahu acooke ahakũre mũhu ũcio wa moori ĩyo na aũige handũ hatarĩ na thaahu nja ya kambĩ. Mũhu ũcio ũigagwo nĩ kĩrĩndĩ kĩa andũ a Isiraeli, nĩgeetha ũhũthagĩrwo maaĩ-inĩ ma kũniina thaahu; ũcio nĩguo wa gũtheranagia kuuma mehia-inĩ.
“Ẹni tó wà ní mímọ́ ni yóò kó eérú ọ̀dọ́ màlúù náà lọ sí ibi tí a yà sí mímọ́ lẹ́yìn ibùdó. Kí gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli kó o pamọ́ fún lílò fún omi ìwẹ̀nùmọ́. Ó jẹ́ ìwẹ̀nùmọ́ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀.
10 Mũndũ ũrĩa ũrĩhakũraga mũhu wa moori ĩyo, no nginya athambie nguo ciake, o nake atiinde arĩ na thaahu nginya hwaĩ-inĩ. Ũndũ ũyũ nĩ watho wa gũtũũra harĩ andũ a Isiraeli na ageni arĩa matũũranagia nao.
Ọkùnrin tí ó kó eérú ọ̀dọ́ abo màlúù náà gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀, òun náà yóò sì jẹ́ aláìmọ́ títí ìrọ̀lẹ́. Èyí ni yóò jẹ́ ìlànà láéláé fún àwọn ọmọ Israẹli àti fún àwọn àjèjì tí ó ń gbé láàrín wọn.
11 “Mũndũ ũrĩa ũngĩhutia kĩimba kĩa mũndũ o na ũrĩkũ arĩikaraga arĩ na thaahu mĩthenya mũgwanja.
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá fi ọwọ́ kan òkú ẹnikẹ́ni, yóò jẹ́ aláìmọ́ fún ọjọ́ méje.
12 No nginya etherie na maaĩ mũthenya wa gatatũ, na mũthenya wa mũgwanja; hĩndĩ ĩyo athirwo nĩ thaahu. No angĩaga gwĩtheria mũthenya wa gatatũ na wa mũgwanja, ndagaathirwo nĩ thaahu.
Ó gbọdọ̀ wẹ ara rẹ̀ pẹ̀lú omi ní ọjọ́ kẹta àti ní ọjọ́ keje; nígbà náà ni yóò jẹ́ mímọ́. Ṣùgbọ́n tí ó bá jẹ́ pé kò wẹ ara rẹ̀ mọ́ ní ọjọ́ kẹta àti ní ọjọ́ keje yóò jẹ́ aláìmọ́.
13 Mũndũ o wothe ũngĩhutia kĩimba kĩa mũndũ o na ũrĩkũ na aage gwĩtheria, ũcio nĩathaahĩtie Hema-ĩrĩa-Nyamũre ya Jehova. Mũndũ ũcio no nginya aingatwo oime Isiraeli. Tondũ ndaminjaminjĩirio maaĩ ma kũniina thaahu, mũndũ ũcio arĩ na thaahu; thaahu wake ndũthirĩte.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá fi ọwọ́ kan òkú ẹnìkan tí kò sì wẹ ara rẹ̀ mọ́, ó ba àgọ́ Olúwa jẹ́. A ó ké irú ẹni bẹ́ẹ̀ kúrò lára àwọn ọmọ Israẹli. Nítorí pé a kò tí ì wọ́n omi ìwẹ̀nùmọ́ lé e lórí, ó jẹ́ aláìmọ́, àìmọ́ rẹ̀ sì wà lára rẹ̀.
14 “Ũyũ nĩguo watho wa kũrũmĩrĩrwo rĩrĩa mũndũ akuĩra hema-inĩ: Mũndũ o na ũrĩkũ ũngĩtoonya hema ĩyo, mũndũ o na ũrĩkũ ũrĩa ũgaakorwo thĩinĩ wayo-rĩ, nĩakanyiitwo nĩ thaahu mĩthenya mũgwanja,
“Èyí ni òfin tí ó jẹ mọ́ bí ènìyàn bá kú nínú àgọ́, ẹnikẹ́ni tí ó bá wọ inú àgọ́ àti ẹni tí ó wà nínú àgọ́ yóò di aláìmọ́ fún ọjọ́ méje,
15 nakĩo kĩndũ o gĩothe kĩa nyũmba gĩgaakorwo gĩtarĩ gĩkunĩke nĩgĩkanyiitwo nĩ thaahu.
gbogbo ohun èlò tí a kò bá fi omọrí dé ni yóò jẹ́ aláìmọ́.
16 “Mũndũ o na ũrĩkũ ũrĩ na kũu nja ũngĩhutia mũndũ ũragĩtwo na rũhiũ rwa njora kana mũndũ ũkuĩte gĩkuũ kĩa ndũire, kana mũndũ o wothe ũngĩhutia ihĩndĩ rĩa mũndũ kana mbĩrĩra, ũcio nĩakanyiitwo nĩ thaahu mĩthenya mũgwanja.
“Ẹnikẹ́ni tí ó bá wà ní ìta tí ó sì fi ọwọ́ kan ẹni tí a fi idà pa tàbí ẹni tí ó kú ikú àtọ̀runwá, tàbí bí ẹnìkan bá fi ọwọ́ kan egungun òkú ènìyàn tàbí isà òkú, yóò jẹ́ aláìmọ́ fún ọjọ́ méje.
17 “Nĩ ũndũ wa mũndũ ũrĩ na thaahu, ĩkĩra mũhu wa moori ĩrĩa yacinĩtwo ĩrĩ ya gũtherania ndigithũ-inĩ, naguo ũitĩrĩrio maaĩ matahĩtwo o hĩndĩ ĩyo.
“Fún aláìmọ́ ènìyàn, mú eérú díẹ̀ lára eérú ọrẹ ìwẹ̀nùmọ́ sínú ìgò, kí o sì da omi tó ń sàn lé e lórí.
18 Nake mũndũ ũtarĩ na thaahu nĩoe mũthobi aũtobokie maaĩ-inĩ macio, na aminjaminjĩrie hema ĩyo na indo ciayo ciothe, na andũ arĩa maarĩ kũu thĩinĩ. Ningĩ no nginya aminjaminjĩrie mũndũ ũrĩa wothe ũhutĩtie ihĩndĩ rĩa mũndũ, kana mbĩrĩra, kana mũndũ ũragĩtwo, kana mũndũ ũkuĩte gĩkuũ kĩa ndũire.
Nígbà náà, ọkùnrin tí a yà sí mímọ́ yóò mú hísópù díẹ̀ yóò rì í sínú omi yóò sì fi wọ́n àgọ́ àti gbogbo ohun èlò tí a ṣe lọ́ṣọ̀ọ́ àti àwọn ènìyàn tí ó wà níbẹ̀. O gbọdọ̀ tún fi wọ́n ẹnikẹ́ni tí ó fi ọwọ́ kan egungun òkú ènìyàn tàbí isà òkú, tàbí ẹni tí ó kú ikú ara rẹ̀, tàbí ẹni tí ó kú ikú àti ọ̀run wá.
19 Mũndũ ũrĩa ũtarĩ na thaahu nĩakaminjaminjĩria mũndũ ũcio ũrĩ na thaahu maaĩ macio mũthenya wa gatatũ na wa mũgwanja, naguo mũthenya wa mũgwanja nĩguo akamũtheria. Nake mũndũ ũcio ũgũtherio no nginya athambie nguo ciake na ethambe mwĩrĩ na maaĩ, naguo hwaĩ-inĩ ũcio nĩagakorwo athirĩtwo nĩ thaahu.
Ọkùnrin tí ó mọ́ ni kí ó bu omi wọ́n àwọn ènìyàn aláìmọ́ ní ọjọ́ kẹta àti ọjọ́ keje, ní ọjọ́ keje ó gbọdọ̀ wẹ ara rẹ̀ mọ́. Ẹni tí a wẹ̀mọ́ gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀ kí ó sì wẹ̀ pẹ̀lú omi, ní ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ náà yóò mọ́.
20 No rĩrĩ, mũndũ ũrĩ na thaahu angĩaga gwĩtheria, no nginya aingatwo kuuma kũrĩ kĩrĩndĩ, nĩ ũndũ nĩathaahĩtie handũ-harĩa-haamũre ha Jehova. Nĩgũkorwo ndaminjaminjĩirio maaĩ ma kũniina thaahu, nĩ ũndũ ũcio arĩ na thaahu.
Ṣùgbọ́n bí ẹni tí ó bá jẹ́ aláìmọ́ kò bá wẹ ara rẹ̀ mọ́, a gbọdọ̀ gé e kúrò nínú ìjọ ènìyàn, nítorí wí pé ó ti ba àgọ́ Olúwa jẹ́. A kò tí ì fi omi ìwẹ̀nùmọ́ sí ara rẹ̀, ó sì jẹ́ aláìmọ́.
21 Ũyũ nĩ watho wao wa gũtũũra. “Mũndũ ũcio wakũminjaminjanĩria maaĩ macio ma kũniina thaahu no nginya o nake athambie nguo ciake, na mũndũ o wothe ũngĩhutia maaĩ macio ma kũniina thaahu nĩagatinda arĩ na thaahu nginya hwaĩ-inĩ.
Èyí jẹ́ ìlànà láéláé fún wọn. “Ọkùnrin tí ó wọ́n omi ìwẹ̀nùmọ́ náà gbọdọ̀ fọ aṣọ rẹ̀ àti ẹnikẹ́ni tí ó fi ọwọ́ kan omi ìwẹ̀nùmọ́ yóò di aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.
22 Kĩndũ gĩothe mũndũ ũrĩ na thaahu akaahutia nĩgĩkanyiitwo nĩ thaahu, na mũndũ ũrĩa ũngĩhutia kĩndũ kĩu nĩagatinda arĩ na thaahu nginya hwaĩ-inĩ.”
Gbogbo ohun tí ẹni tí ó jẹ́ aláìmọ́ bá fi ọwọ́ kàn yóò di àìmọ́, ẹnikẹ́ni tí ó bá sì fi ọwọ́ kàn án yóò jẹ́ aláìmọ́ títí di ìrọ̀lẹ́.”

< Ndari 19 >