< Luka 8 >

1 Na rĩrĩ, thuutha wa ũguo, Jesũ agĩthiĩ matũũra-inĩ o na tũtũũra-inĩ akĩhunjagia Ũhoro-ũrĩa-Mwega wa ũthamaki wa Ngai. Arutwo ake arĩa ikũmi na eerĩ maarĩ hamwe nake,
Ó sì ṣe lẹ́yìn náà, tí ó ń lá gbogbo ìlú àti ìletò kọjá lọ, ó ń wàásù, ó ń ròyìn ayọ̀ ìjọba Ọlọ́run. Àwọn méjìlá sì ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀,
2 o na atumia amwe a arĩa maarutĩtwo ngoma thũku na arĩa maahonetio mĩrimũ: nao nĩ Mariamu (ũrĩa wetagwo Mũmagidali), nĩwe warutĩtwo ndaimono mũgwanja;
àti àwọn obìnrin kan, tí a ti mú láradá kúrò lọ́wọ́ àwọn ẹ̀mí búburú àti nínú àìlera wọn, Maria tí a ń pè ní Magdalene, lára ẹni tí ẹ̀mí èṣù méje ti jáde kúrò.
3 na Joana mũtumia wa Husa, ũrĩa warĩ mũrori wa indo cia Herode; na Susana; na angĩ aingĩ. Atumia aya nĩmamũtungatagĩra na indo ciao ene.
Àti Joanna aya Kusa tí í ṣe ìríjú Herodu, àti Susana, àti àwọn púpọ̀ mìíràn, tí wọ́n ń ṣe ìránṣẹ́ fún un nínú ohun ìní wọn.
4 Andũ aingĩ nĩmathiire na mbere kũngana harĩ Jesũ moimĩte matũũra-inĩ, na rĩrĩa andũ maingĩhire mũno akĩmahe ũhoro na ngerekano, akĩmeera atĩrĩ,
Nígbà tí ọ̀pọ̀ ìjọ ènìyàn péjọpọ̀, àwọn ènìyàn láti ìlú gbogbo sì tọ̀ ọ́ wá, ó fi òwe bá wọn sọ̀rọ̀ pé,
5 Mũrĩmi nĩoimagarire akahure mbeũ ciake. Na rĩrĩa aahuraga mbeũ icio, imwe ikĩgũa mũkĩra-inĩ wa njĩra; ikĩrangĩrĩrio na magũrũ, nacio nyoni cia rĩera-inĩ igĩũka igĩcirĩa.
“Afúnrúgbìn kan jáde lọ láti fún irúgbìn rẹ̀: bí ó sì ti ń fúnrúgbìn, díẹ̀ bọ́ sí ẹ̀bá ọ̀nà, a sì tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀, àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run sì ṣà á jẹ.
6 Ingĩ ikĩgũa rũnyanjara-inĩ, na rĩrĩa ciamerire, mĩmera ĩyo ĩkĩhooha tondũ wa kwaga ũigũ.
Òmíràn sì bọ́ sórí àpáta; bí ó sì ti hù jáde, ó gbẹ nítorí tí kò ní omi.
7 Nacio mbeũ ingĩ ikĩgũa mĩigua-inĩ, nayo mĩigua ĩgĩkũranĩra nacio na ĩgĩcithararia.
Òmíràn sì bọ́ sínú ẹ̀gún; ẹ̀gún sì dàgbà pẹ̀lú rẹ̀ sókè, ó sì fún un pa.
8 Mbeũ ingĩ nacio ikĩgũa tĩĩri-inĩ mũnoru. Igĩkũra, igĩciara maita igana ma iria ciahaandĩtwo. Aarĩkia kuuga ũguo, akĩanĩrĩra, akiuga atĩrĩ, “Ũrĩa ũrĩ na matũ ma kũigua, nĩaigue.”
Òmíràn sì bọ́ sí ilẹ̀ rere, ó sì hù sókè, ó sì so èso ọ̀rọ̀ọ̀rún ju èyí ti a gbin lọ.” Nígbà tí ó sì wí nǹkan wọ̀nyí tán, ó pariwo sókè pé, “Ẹni tí ó bá ní etí láti fi gbọ́, kí ó gbọ́!”
9 Nao arutwo ake makĩmũũria ũrĩa ngerekano ĩyo yoigaga.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì bi í léèrè, pé, “Kí ni a lè mọ òwe yìí sí?”
10 Akĩmeera atĩrĩ, “Inyuĩ nĩmũheetwo ũmenyo wa kũmenya hitho cia ũthamaki wa Ngai, no arĩa angĩ ndĩmaaragĩria na ngerekano, nĩgeetha, “‘maarora, makaaga kuona; na maigua, makaaga gũtaũkĩrwo.’
Ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ni a fi fún láti mọ ohun ìjìnlẹ̀ ìjọba Ọlọ́run; ṣùgbọ́n fún àwọn ẹlòmíràn wọn yóò jẹ́ òwe, pé ní rí rí, “‘kí wọn má ba à rí, àti ní gbígbọ́ kí ó má lè yé wọn.’
11 “Ngerekano ĩyo yugĩte atĩrĩ: Mbeũ icio nĩ ũhoro wa Ngai.
“Ǹjẹ́ òwe náà ni èyí: irúgbìn ni ọ̀rọ̀ Ọlọ́run.
12 Mbeũ iria ciagũire mũkĩra-inĩ wa njĩra nĩ andũ arĩa maiguaga ũhoro wa Ngai, nake mũcukani agooka akeheria ũhoro ũcio ngoro-inĩ ciao, nĩguo matigetĩkie mahonoke.
Àwọn ti ẹ̀bá ọ̀nà ni àwọn tí ó gbọ́ nígbà náà ni èṣù wá ó sì mú ọ̀rọ̀ náà kúrò ní ọkàn wọn, kí wọn má ba à gbàgbọ́, kí a sì gbà wọ́n là.
13 Nacio iria ciagũire rũnyanjara-inĩ nĩ andũ arĩa maiguaga ũhoro wa Ngai, na makawamũkĩra na gĩkeno, no makaaga mĩri. Metĩkagia o gwa kahinda kanini, no magerio moka makaũtiganĩria.
Àwọn ti orí àpáta ni àwọn, tí wọ́n gbọ́, wọ́n fi ayọ̀ gba ọ̀rọ̀ náà, àwọn wọ̀nyí kò sì ní gbòǹgbò, wọ́n á gbàgbọ́ fún sá à díẹ̀; nígbà ìdánwò, wọn á padà sẹ́yìn.
14 Mbeũ iria ciagũire mĩigua-inĩ nĩ andũ arĩa maiguaga ũhoro, no o magĩthiiaga-rĩ, magatharario nĩ mĩhangʼo, na ũtonga, na mĩago, nao makaaga gũkũra.
Àwọn tí ó bọ́ sínú ẹ̀gún ni àwọn, tí wọ́n gbọ́ tán, wọ́n ti n lọ, wọn a sì fi ìtọ́jú àti ọrọ̀ àti ìrora ayé fún un pa, wọn kò sì lè so èso àsogbó.
15 No rĩrĩ, mbeũ iria ciagũire tĩĩri-inĩ ũrĩa mũnoru nĩ andũ arĩa maiguaga ũhoro marĩ na ngoro ya ma na njega, makaũtũũria, na nĩ ũndũ wa gũkirĩrĩria, magaciaraga maciaro.
Ṣùgbọ́n ti ilẹ̀ rere ni àwọn tí wọ́n fi ọkàn òtítọ́ àti rere gbọ́ ọ̀rọ̀ náà, wọ́n dìímú ṣinṣin, wọ́n sì fi sùúrù so èso.
16 “Na rĩrĩ, gũtirĩ mũndũ ũgwatagia tawa akaũkunĩkĩria na irebe, kana akaũiga rungu rwa ũrĩrĩ. No aũigaga handũ igũrũ, nĩguo andũ arĩa megũtoonya nyũmba mathererwo nĩ ũtheri.
“Kò sí ẹnikẹ́ni, nígbà tí ó bá tán fìtílà tan, tí yóò fi ohun èlò bò ó mọ́lẹ̀, tàbí tí yóò gbé e sábẹ́ àkéte; bí kò ṣe kí ó gbé e ka orí ọ̀pá fìtílà, kí àwọn tí ń wọ ilé lè rí ìmọ́lẹ̀.
17 Nĩgũkorwo gũtirĩ ũndũ mũhithe ũtakaguũrio, na gũtirĩ ũndũ ũrĩ hitho-inĩ ũtakamenyeka kana ũtakanĩkwo ũtheri-inĩ.
Nítorí kò sí ohun tí ó fi ara sin, tí a kì yóò fihàn, tàbí ohun tí a fi pamọ́, ti a kì yóò sì mọ̀ kí ó sì yọ sí gbangba.
18 Nĩ ũndũ ũcio mwĩmenyagĩrĩrei ũrĩa mũthikagĩrĩria. Ũrĩa wothe ũrĩ na indo nĩakongererwo nyingĩ; na ũrĩa wothe ũtarĩ nĩagatuunywo o na kĩrĩa arĩ nakĩo.”
Ǹjẹ́ kí ẹ̀yin máa kíyèsára bí ẹ̀yin ti ń gbọ́: nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá ní, lọ́wọ́ rẹ̀ ni a ó sì gba èyí tí ó ṣe bí òun ní.”
19 Na rĩrĩ, nyina wa Jesũ na ariũ a nyina na Jesũ magĩũka kũmuona, no matingĩahotire gũthiĩ hakuhĩ nake nĩ ũndũ wa andũ kũingĩha.
Nígbà náà ní ìyá rẹ̀ àti àwọn arákùnrin rẹ̀ tọ̀ ọ́ wá, wọn kò sì lè súnmọ́ ọn nítorí ọ̀pọ̀ ènìyàn.
20 Mũndũ ũmwe akĩmwĩra atĩrĩ, “Maitũguo na ariũ a maitũguo marũgamĩte nja makĩenda gũkuona.”
Wọ́n sì wí fún un pé, “Ìyá rẹ àti àwọn arákùnrin rẹ dúró lóde, wọn fẹ́ rí ọ.”
21 Nake akĩmũcookeria atĩrĩ, “Maitũ na ariũ a maitũ nĩ arĩa maiguaga ũhoro wa Ngai na makaũhingia.”
Ó sì dáhùn wí fún wọn pé, “Ìyá mi àti àwọn arákùnrin mi ni àwọn wọ̀nyí tí wọ́n ń gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, tí wọ́n sì ń ṣe é.”
22 Mũthenya ũmwe Jesũ nĩerire arutwo ake atĩrĩ, “Nĩtũringei tũthiĩ mũrĩmo ũrĩa ũngĩ wa iria.” Nĩ ũndũ ũcio magĩtoonya gatarũ magĩthiĩ.
Ní ọjọ́ kan, ó sì wọ ọkọ̀ ojú omi kan lọ òun pẹ̀lú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀. O sì wí fún wọn pé, “Ẹ jẹ́ kí a rékọjá lọ sí ìhà kejì adágún.” Wọ́n sì ṣíkọ̀ láti lọ.
23 Na rĩrĩa maathiiaga Jesũ akĩhĩtwo nĩ toro. Na rĩrĩ, kũu iria-inĩ nĩ kwagĩire na kĩhuhũkanio kĩnene, nako gatarũ kau kaarĩ hakuhĩ kũũrĩra maaĩ-inĩ, na magĩkorwo marĩ ũgwati-inĩ mũnene.
Bí wọ́n sì ti ń lọ, ó sùn; ìjì ńlá sì dé, ó ń fẹ́ lójú adágún; omi si wọ inú ọkọ, wọ́n sì wà nínú ewu.
24 Nao arutwo magĩthiĩ makĩmũũkĩria, makĩmwĩra atĩrĩ “Mwathani! Mwathani! Nĩtũkũũrĩra maaĩ-inĩ!” Nake Jesũ agĩũkĩra agĩkaania rũhuho na maaĩ macio maahũũranaga; namo makũmbĩ macio ma maaĩ makĩnyihanyiiha na gũkĩhoorera.
Wọ́n sì tọ̀ ọ́ wá wọ́n sì jí i, wí pé, “Olùkọ́, Olùkọ́, àwa yóò ṣègbé!” Nígbà náà ni ó dìde, ó sì bá ìjì líle àti ríru omi wí; wọ́n sì dúró, ìdákẹ́rọ́rọ́ sì dé.
25 Akĩũria arutwo ake atĩrĩ, “Wĩtĩkio wanyu ũrĩ ha?” Nao makĩiyũrwo nĩ guoya na makĩgega, makĩũrania atĩrĩ, “Kaĩ mũndũ ũyũ arĩ ũ? Aathaga huho o na maaĩ, nacio ikamwathĩkĩra.”
Ó sì wí fún wọn pé, “Ìgbàgbọ́ yín dà?” Bí ẹ̀rù ti ń ba gbogbo wọn, tí hà sì ń ṣe wọ́n, wọ́n ń bi ara wọn pé, “Irú ọkùnrin wo ni èyí, nítorí ó bá ìjì líle àti ríru omi wí, wọ́n sì gbọ́ tirẹ̀?”
26 Makĩringa mũrĩmo ũrĩa ũngĩ wa iria, magĩkinya rũgongo rwa Agerasi rũrĩa rũngʼethanĩire na Galili.
Wọ́n sì gúnlẹ̀ ní ilẹ̀ àwọn ará Gadara, tí ó kọjú sí Galili.
27 Jesũ aarĩkia kuuma gatarũ, aakinya thĩ agĩtũngwo nĩ mũndũ warĩ na ndaimono oimĩte itũũra-inĩ. Mũndũ ũcio nĩaikarĩte ihinda inene ategwĩkĩra nguo kana agatũũra nyũmba, no aatũũraga mbĩrĩra-inĩ.
Nígbà tí ó sì sọ̀kalẹ̀, ọkùnrin kan pàdé rẹ̀ lẹ́yìn ìlú náà, tí ó ti ní àwọn ẹ̀mí èṣù fún ìgbà pípẹ́, tí kì í wọ aṣọ, bẹ́ẹ̀ ni kì í jókòó ní ilé kan, bí kò ṣe ní ibojì.
28 Rĩrĩa mũndũ ũcio onire Jesũ, agĩkaya na akĩĩgũithia magũrũ-inĩ make, akĩanĩrĩra na mũgambo mũnene akĩmũũria atĩrĩ, “Ũrenda atĩa na niĩ, wee Jesũ, Mũrũ wa Ngai-Ũrĩa-ũrĩ-Igũrũ-Mũno? Ndagũthaitha, ndũkaanyariire!”
Nígbà tí ó rí Jesu, ó ké, ó wólẹ̀ níwájú rẹ̀, ó wí lóhùn rara, pé, “Kí ni mo ní í ṣe pẹ̀lú rẹ, Jesu, ìwọ Ọmọ Ọlọ́run Ọ̀gá-ògo? Èmi bẹ̀ ọ́ má ṣe dá mi lóró.”
29 Nĩgũkorwo Jesũ nĩathĩte ngoma ĩyo thũku yume thĩinĩ wa mũndũ ũcio. Nĩyamũnyiitaga kaingĩ, na o na gũtuĩka nĩoohagwo moko na magũrũ na mĩnyororo, na akarangĩrwo-rĩ, nĩatuangaga mĩnyororo ĩyo yamuohaga, na ndaimono ĩyo ĩgatũma athiĩ kũndũ gũtarĩ andũ.
(Nítorí tí ó ti wí fún ẹ̀mí àìmọ́ náà pé, kí ó jáde kúrò lára ọkùnrin náà. Nígbàkígbà ni ó ń mú un: wọn a sì fi ẹ̀wọ̀n àti ṣẹ́kẹ́ṣẹkẹ̀ dè é; a sì ja gbogbo ìdè náà, ẹ̀mí èṣù náà a sì darí rẹ̀ sí ijù).
30 Jesũ akĩmũũria atĩrĩ, “Wĩtagwo atĩa?” Nake akĩmũcookeria atĩrĩ, “Legioni,” nĩgũkorwo aarĩ na ndaimono nyingĩ.
Jesu sì bi í pé, “Kí ni orúkọ rẹ?” Ó sì dáhùn pé, “Ligioni,” nítorí ẹ̀mí èṣù púpọ̀ ni ó wa nínú rẹ.
31 Nacio ndaimono igĩkĩrĩrĩria gũthaitha Jesũ ndagaciathe ithiĩ Irima-rĩrĩa-Rĩtarĩ-Gĩturi. (Abyssos g12)
Wọ́n sì bẹ̀ ẹ́ pé, kí ó má ṣe rán wọn lọ sínú ọ̀gbun. (Abyssos g12)
32 Na rĩrĩ, nĩ haarĩ na rũũru rũnene rwa ngũrwe rwarĩithagio harũrũka-inĩ cia kĩrĩma kĩarĩ hakuhĩ na hau. Ndaimono icio igĩthaitha Jesũ aciĩtĩkĩrie itoonye thĩinĩ wacio, nake agĩciĩtĩkĩria.
Agbo ẹlẹ́dẹ̀ púpọ̀ sì ń bẹ níbẹ̀ tí ń jẹ lórí òkè: wọ́n sì bẹ̀ ẹ́ kí ó jẹ́ kí àwọn wọ inú wọn lọ. Ó sì gba fún wọn.
33 Ndaimono cioima thĩinĩ wa mũndũ ũcio, igĩthiĩ igĩtoonya ngũrwe, naruo rũũru rũu rũkĩharũrũka kĩhurũrũka kĩu na ihenya, rũkĩgũa iria-inĩ, rũkĩũrĩra kuo.
Nígbà tí àwọn ẹ̀mí èṣù sì jáde kúrò lára ọkùnrin náà, wọ́n sì wọ inú àwọn ẹlẹ́dẹ̀ lọ. Agbo ẹlẹ́dẹ̀ sì tú ka, wọ́n sí súré rọ́ gììrì sọ̀kalẹ̀ sì bèbè odò bọ́ sínú adágún náà, wọ́n sì rì sínú rẹ̀.
34 Rĩrĩa andũ arĩa maarĩithagia ngũrwe icio moonire ũrĩa gwekĩka, makĩũra, magĩthiĩ kũheana ũhoro ũcio itũũra-inĩ na mĩgũnda-inĩ,
Nígbà tí àwọn tí n bọ́ wọn rí ohun tí ó ṣẹlẹ̀, wọ́n sá, wọ́n sì lọ, wọ́n sì ròyìn ní ìlú àti ní ilẹ̀ náà.
35 nao andũ makiumagara makone ũndũ ũcio wekĩkĩte. Rĩrĩa maakinyire harĩ Jesũ na makĩona mũndũ ũcio woimĩtwo nĩ ndaimono aikarĩte magũrũ-inĩ ma Jesũ, arĩ na nguo na arĩ na meciiria mega, magĩĩtigĩra mũno.
Nígbà náà ni wọ́n jáde lọ wo ohun náà tí ó ṣẹlẹ̀, wọ́n sì tọ Jesu wá, wọ́n sì rí ọkùnrin náà, lára ẹni tí àwọn ẹ̀mí èṣù ti jáde lọ, ó jókòó lẹ́bàá ẹsẹ̀ Jesu, ó wọ aṣọ, iyè rẹ̀ sì bọ́ sí ipò: ẹ̀rù sì bà wọ́n.
36 Andũ arĩa meyoneire ũndũ ũcio makĩĩra andũ acio angĩ ũrĩa mũndũ ũcio warĩ na ndaimono aahonetio.
Àwọn tí ó rí i ròyìn fún wọn bí ó ti ṣe mú ẹni tí ó ní ẹ̀mí èṣù náà láradá.
37 Nao andũ othe a rũgongo rũu rwa Agerasi magĩthaitha Jesũ oime kũu kwao amatige, nĩgũkorwo nĩmanyiitĩtwo nĩ guoya. Nĩ ũndũ ũcio Jesũ agĩtoonya gatarũ agĩthiĩ.
Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn láti ilẹ̀ Gadara yíká bẹ̀ ẹ́ pé, kí ó lọ kúrò lọ́dọ̀ wọn; nítorí ẹ̀rù bà wọ́n gidigidi. Ó sì bọ́ sínú ọkọ̀ ojú omi, ó si kúrò.
38 Nake mũndũ ũcio warutĩtwo ndaimono akĩmũthaitha mathiĩ nake, no Jesũ akĩmwatha athiĩ, akĩmwĩra atĩrĩ,
Ǹjẹ́ ọkùnrin náà tí ẹ̀mí èṣù jáde kúrò lára rẹ̀, bẹ̀ ẹ́ kí òun lè máa bá a gbé: ṣùgbọ́n Jesu rán an lọ, wí pé,
39 “Cooka mũciĩ ũkoige ũrĩa wothe Ngai agwĩkĩire.” Nĩ ũndũ ũcio mũndũ ũcio agĩthiĩ akĩĩra andũ othe a itũũra ũrĩa Jesũ aamwĩkĩire.
“Padà lọ sí ilé rẹ, kí o sì sọ ohun tí Ọlọ́run ṣe fún ọ bí ó ti pọ̀ tó.” Ó sì lọ, o sì ń ròyìn ka gbogbo ìlú náà bí Jesu ti ṣe ohun ńlá fún òun tó.
40 Na rĩrĩ, Jesũ aacooka kuuma mũrĩmo ũũrĩa ũngĩ wa iria, andũ aingĩ nĩmamwamũkĩrire tondũ nĩmamwetereire.
Ó sì ṣe, nígbà tí Jesu padà lọ, àwọn ènìyàn tẹ́wọ́gbà á; nítorí tí gbogbo wọn ti ń retí rẹ̀.
41 Hĩndĩ ĩyo mũndũ wetagwo Jairũ warĩ mũnene wa thunagogi agĩũka, akĩĩgũithia magũrũ-inĩ ma Jesũ, akĩmũthaitha athiĩ gwake,
Sì kíyèsi i, ọkùnrin kan tí a ń pè ní Jairu, ọ̀kan nínú àwọn olórí Sinagọgu wá; ó sì wólẹ̀ lẹ́bàá ẹsẹ̀ Jesu, ó bẹ̀ ẹ́ pé, kí ó wá sí ilé òun,
42 nĩ ũndũ mũirĩtu wake wa mũmwe warĩ wa ta mĩaka ikũmi na ĩĩrĩ aarĩ hakuhĩ gũkua. Na Jesũ arĩ njĩra-inĩ agĩthiĩ-rĩ, andũ nĩmamũhatĩkaga.
nítorí ó ní ọmọbìnrin kan ṣoṣo, ọmọ ìwọ̀n ọdún méjìlá, ti ó ń kú lọ. Bí ó sì ti ń lọ àwọn ènìyàn ko fun ni ààyè.
43 Gatagatĩ-inĩ ka andũ acio nĩ haarĩ na mũtumia ũmwe watũire oiraga thakame mĩaka ikũmi na ĩĩrĩ, na gũtirĩ mũndũ ũngĩamũhonirie.
Obìnrin kan tí ó sì ní ìsun ẹ̀jẹ̀ láti ìgbà ọdún méjìlá, tí ó ná ohun gbogbo tí ó ní fún àwọn oníṣègùn, tí kò sì sí ẹnìkan tí ó lè mú un láradá,
44 Mũtumia ũcio agĩũka na thuutha wa Jesũ, akĩhutia gĩcũrĩ kĩa nguo yake, na o rĩmwe agĩtiga kuura.
Ó wá sí ẹ̀yìn rẹ̀, ó fi ọwọ́ tọ́ ìṣẹ́tí aṣọ rẹ̀; lọ́gán ni ìsun ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sì ti gbẹ.
45 Nake Jesũ akĩũria atĩrĩ, “Nũũ ũcio wahutia?” Rĩrĩa othe maakaanire, Petero akĩmwĩra atĩrĩ, “Mwathani, andũ nĩmagũthiũrũrũkĩirie na magakũhatĩka.”
Jesu sì wí pé, “Ta ni ó fi ọwọ́ kàn mí?” Nígbà tí gbogbo wọn sẹ́ Peteru àti àwọn tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ sọ pé, “Olùkọ́, àwọn ènìyàn ko ní ààyè, wọ́n sì ń kọlù ọ́, ìwọ sì wí pé, Ta ni ó fi ọwọ́ kàn mi?”
46 Nowe Jesũ akiuga atĩrĩ, “Nĩ harĩ mũndũ waahutia, tondũ nĩndaigua hinya woima thĩinĩ wakwa.”
Jesu sì wí pé, “Ẹnìkan fi ọwọ́ kàn mí: nítorí tí èmí mọ̀ pé, àṣẹ jáde lára mi.”
47 Nake mũtumia ũcio, ona atĩ ndangĩhota kwĩhitha, agĩũka akĩinainaga, akĩĩgũithia magũrũ-inĩ make. Arĩ hau mbere ya andũ othe akĩheana gĩtũmi kĩrĩa gĩatũmĩte amũhutie na ũrĩa aahonirio o ro rĩmwe.
Nígbà tí obìnrin náà sì mọ̀ pé òun kò fi ara sin, ó wárìrì, ó wá, ó sì wólẹ̀ níwájú rẹ̀, ó sì sọ fún un lójú àwọn ènìyàn gbogbo nítorí ohun tí ó ṣe, tí òun fi fi ọwọ́ kàn án, àti bí a ti mú òun láradá lójúkan náà.
48 Nake Jesũ akĩmwĩra atĩrĩ, “Mwarĩ ũyũ, gwĩtĩkia gwaku nĩkuo gwatũma ũhone. Thiĩ na thayũ.”
Ó sì wí fún un pé, “Ọmọbìnrin, ìgbàgbọ́ rẹ mú ọ láradá, máa lọ ní Àlàáfíà.”
49 Na o hĩndĩ ĩyo Jesũ akĩaragia, hagĩkinya mũndũ woimĩte mũciĩ kwa Jairũ ũrĩa mũnene wa thunagogi, akiuga atĩrĩ, “Mwarĩguo nĩarĩkĩtie gũkua, tiga gũthĩĩnia Mũrutani.”
Bí ó sì ti ń sọ̀rọ̀ lẹ́nu, ẹnìkan ti ilé olórí Sinagọgu wá, ó wí fún un pé, “Ọmọbìnrin rẹ kú; má yọ olùkọ́ni lẹ́nu mọ́.”
50 Jesũ aigua ũguo, akĩĩra Jairũ atĩrĩ, “Tiga gwĩtigĩra, wee ĩtĩkia tu, na nĩekũhona.”
Ṣùgbọ́n nígbà tí Jesu gbọ́, ó dá a lóhùn, pé, “Má bẹ̀rù: sá gbàgbọ́ nìkan, a ó sì mú un láradá.”
51 Rĩrĩa aakinyire kwa Jairũ, ndaarekire mũndũ o na ũmwe atoonye hamwe nake, tiga o Petero, na Jakubu, na Johana, na ithe na nyina a mwana ũcio.
Ṣùgbọ́n nígbà tí Jesu sì wọ ilé, kò jẹ́ kí ẹnikẹ́ni wọlé, bí kò ṣe Peteru, àti Jakọbu, àti Johanu, àti baba àti ìyá ọmọbìnrin náà.
52 Hĩndĩ ĩyo andũ othe no kũrĩra maarĩraga magĩcakayaga nĩ ũndũ wa mwana ũcio. Jesũ akĩmeera atĩrĩ, “Tigai kũrĩra, ti mũkuũ, nĩ gũkoma akomete.”
Gbogbo wọn sì sọkún, wọ́n pohùnréré ẹkún rẹ̀: ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ má sọkún mọ́; kò kú, sísùn ni ó sùn.”
53 Nao makĩmũthekerera, tondũ nĩmooĩ atĩ aarĩ mũkuũ.
Wọ́n sì fi í ṣẹ̀fẹ̀, wọ́n sá mọ̀ pé ó kú.
54 Nowe Jesũ akĩnyiita mwana ũcio guoko, akiuga atĩrĩ, “Mwana wakwa, ũkĩra!”
Nígbà tí ó sì sé gbogbo wọn mọ́ òde, ó mú un lọ́wọ́, ó sì wí pé, “Ọmọbìnrin, dìde!”
55 Na hĩndĩ o ĩyo agĩcookererwo nĩ muoyo wake, na o rĩmwe akĩrũgama. Jesũ agĩcooka akĩmeera mahe mwana ũcio kĩndũ gĩa kũrĩa.
Ẹ̀mí rẹ̀ sì padà bọ̀, ó sì dìde lọ́gán: ó ní kí wọn fún un ní oúnjẹ.
56 Nao aciari ake makĩgega mũno, nowe akĩmaatha matikeere mũndũ o na ũ ũndũ ũcio wekĩkĩte.
Ẹnu sì ya àwọn òbí rẹ̀: ṣùgbọ́n ó kìlọ̀ fún wọn pé, kí wọn má ṣe wí fún ẹnìkan ohun tí a ṣe.

< Luka 8 >