< Alawii 2 >
1 “‘Hĩndĩ ĩrĩa mũndũ arĩrehagĩra Jehova iruta rĩa ngano-rĩ, iruta rĩake no nginya rĩkorwo rĩrĩ rĩa mũtu ũrĩa mũhinyu mũno. Nĩaũitĩrĩrie maguta na awĩkĩre ũbani,
“‘Bí ẹnìkan bá mú ọrẹ ẹbọ ohun jíjẹ wá fún Olúwa ọrẹ rẹ̀ gbọdọ̀ jẹ́ ìyẹ̀fun dáradára, kí ó da òróró sí i, kí o sì fi tùràrí sí i,
2 acooke aũtwarĩre ariũ a Harũni acio athĩnjĩri-Ngai. Mũthĩnjĩri-Ngai nĩakarũma ngundi ya mũtu ũcio mũhinyu mũno ũrĩ na maguta hamwe na ũbani ũcio wothe, na aũcinĩre igũrũ rĩa kĩgongona ũtuĩke gĩcunjĩ gĩa kĩririkano, ũrĩ iruta rĩa gũcinwo na mwaki, rĩrĩ na mũtararĩko mwega wa gũkenia Jehova.
kí ó sì gbé lọ fún àwọn ọmọ Aaroni tí í ṣe àlùfáà. Àlùfáà yóò bu ẹ̀kúnwọ́ kan nínú ìyẹ̀fun àti òróró náà, pẹ̀lú gbogbo tùràrí kí ó sì sun ún gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ìrántí lórí pẹpẹ, ọrẹ tí a fi iná ṣe, àní òórùn dídùn sí Olúwa.
3 Mũtu ũrĩa ũrĩtigaraga wa iruta rĩu rĩa mũtu nĩ wa Harũni na ariũ ake; nĩ gĩcunjĩ gĩtheru mũno kĩa iruta rĩrĩa rĩrutĩirwo Jehova na mwaki.
Ìyókù nínú ọrẹ ohun jíjẹ náà jẹ́ ti Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀, ó jẹ́ ìpín tí ó mọ́ jùlọ nínú ọrẹ tí a fi iná sun sí Olúwa.
4 “‘Mũngĩrehe iruta rĩa mũtu rĩhĩhĩirio riiko, nĩrĩkorwo rĩrĩ rĩa mũtu mũhinyu mũno, keki irugĩtwo itarĩ na ndawa ya kũimbia, itukanĩtio na maguta, kana tũmĩgate tũhũthũ tũtarĩ na ndawa ya kũimbia tũhakĩtwo maguta.
“‘Bí ẹ bá mú ọrẹ ohun jíjẹ, èyí tí a yan lórí ààrò iná, kí ó jẹ́ ìyẹ̀fun kíkúnná dáradára, àkàrà tí a ṣe láìní ìwúkàrà, tí a sì fi òróró pò àti àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ tí a ṣe láìní ìwúkàrà èyí tí a fi òróró pò.
5 Angĩkorwo iruta rĩanyu rĩa mũtu nĩ mũgate ũkarangĩirwo igũrũ wa rũgĩo-rĩ, no nginya ũthondekwo na mũtu ũrĩa mũhinyu mũno ũtukanĩtio na maguta, na ũtarĩ na ndawa ya kũimbia.
Bí ọrẹ ẹbọ rẹ bá jẹ́ inú àwo pẹẹrẹ ni o ti ṣe ohun jíjẹ rẹ, kí ó jẹ́ ìyẹ̀fun dáradára tí a fi òróró pò, kò sì gbọdọ̀ ní ìwúkàrà.
6 Ũwenyũrange cienyũ, ũũitĩrĩrie maguta; rĩu nĩ iruta rĩa mũtu.
Rún un kí o sì da òróró sí i lórí, ọrẹ ohun jíjẹ ni.
7 Igongona rĩanyu rĩa mũtu rĩngĩgakorwo nĩ mũgate ũkarangĩirwo igũrũ rĩa rũgĩo-rĩ, igongona rĩu nĩrĩthondekwo na mũtu ũrĩa mũhinyu mũno na maguta.
Bí ọrẹ ẹbọ rẹ bá jẹ́ ẹbọ ohun jíjẹ, tí a yan nínú apẹ, ìyẹ̀fun dáradára ni kí o fi ṣè é pẹ̀lú òróró.
8 Reherai Jehova iruta rĩa mũtu rĩthondeketwo na indo icio; rĩneanwo kũrĩ mũthĩnjĩri-Ngai, nake arĩtware kĩgongona-inĩ.
Mú ọrẹ ohun jíjẹ tí a fi àwọn nǹkan wọ̀nyí ṣe wá fún Olúwa gbé e fún àlùfáà, ẹni tí yóò gbe e lọ sí ibi pẹpẹ.
9 Mũthĩnjĩri-Ngai nĩakaruta gĩcunjĩ gĩa kĩririkano kuuma iruta rĩu rĩa mũtu na arĩcinĩre igũrũ rĩa kĩgongona kĩu, rĩrĩ iruta rĩa gũcinwo na mwaki, rĩrĩ na mũtararĩko mwega wa gũkenia Jehova.
Àlùfáà yóò sì mú ẹbọ ìrántí nínú ọrẹ ohun jíjẹ yìí, yóò sì sun ún lórí pẹpẹ gẹ́gẹ́ bí ọrẹ tí a fi iná sun, àní òórùn dídùn sí Olúwa.
10 Mũtu ũrĩa ũrĩtigaraga wa iruta rĩu rĩa mũtu nĩ wa Harũni na ariũ ake; nĩ gĩcunjĩ gĩtheru mũno kĩa iruta rĩrĩa rĩrutĩirwo Jehova na mwaki.
Ìyókù nínú ọrẹ ohun jíjẹ yìí jẹ́ ti Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀, ó jẹ́ èyí tí ó mọ́ jùlọ nínú ọrẹ tí a fi iná sun sí Olúwa.
11 “‘Iruta o rĩothe rĩa mũtu rĩrĩa mũrĩrehagĩra Jehova no nginya rĩthondekagwo rĩtarĩ na ndawa ya kũimbia, nĩgũkorwo mũtigaacina ndawa ya kũimbia kana ũũkĩ mũkĩrutĩra Jehova iruta rĩa gũcinwo na mwaki.
“‘Gbogbo ọrẹ ohun jíjẹ tí ẹ bá mú wá fún Olúwa kò gbọdọ̀ ní ìwúkàrà nínú, nítorí pé ẹ kò gbọdọ̀ sun ohun wíwú tàbí oyin nínú ọrẹ tí ẹ fi iná sun sí Olúwa.
12 Indo icio no mũcirutĩre Jehova irĩ iruta rĩa maciaro ma mbere, no itikarutwo kĩgongona-inĩ irĩ ta mũtararĩko mwega.
Ẹ lè mú wọn wá fún Olúwa gẹ́gẹ́ bí ọrẹ àkọ́so ṣùgbọ́n ẹ kò gbọdọ̀ mú wọn wá sórí pẹpẹ gẹ́gẹ́ bí òórùn dídùn.
13 Nĩ mũgekĩraga cumbĩ maruta-inĩ manyu mothe ma mũtu. Mũtikanaage gwĩkĩra cumbĩ wa kĩrĩkanĩro kĩa Ngai wanyu maruta-inĩ manyu ma mũtu; ĩkĩragai cumbĩ maruta-inĩ manyu mothe.
Ẹ fi iyọ̀ dun gbogbo ọrẹ ohun jíjẹ yín. Ẹ má ṣe aláìfi iyọ̀ májẹ̀mú Ọlọ́run yín sínú àwọn ọrẹ ohun jíjẹ yín, ẹ fi iyọ̀ sí gbogbo ọrẹ yín.
14 “‘Mũngĩkarehere Jehova iruta rĩa mũtu rĩa maciaro ma mbere-rĩ, heanai mũtu wa ngano ya mũgethano ĩrĩ hĩhie na mwaki.
“‘Bí ẹ bá mú ọrẹ ohun jíjẹ ti àkọ́so oko yín wá fún Olúwa kí ẹ mú ọkà tuntun tí a fi iná yan.
15 Na mwĩkĩre maguta na ũbani igũrũ rĩayo; rĩu nĩ iruta rĩa mũtu.
Kí ẹ da òróró lé e lórí, kí ẹ sì fi tùràrí sí i, ó jẹ́ ọrẹ ohun jíjẹ.
16 Mũthĩnjĩri-Ngai nĩagacina gĩcunjĩ gĩa kĩririkano kĩa ngano thĩye ĩrĩ na maguta hamwe na ũbani wothe, rĩrĩ iruta rĩrutĩirwo Jehova na mwaki.
Àlùfáà yóò sun ẹbọ ìrántí lára ọkà àti òróró náà, pẹ̀lú gbogbo tùràrí gẹ́gẹ́ bí ọrẹ tí a fi iná sun sí Olúwa.