< Atiirĩrĩri 17 >
1 Na rĩrĩ, mũndũ wetagwo Mika wa kuuma bũrũri ũrĩa ũrĩ irĩma wa Efiraimu
Nígbà náà ni ọkùnrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Mika láti agbègbè òkè Efraimu
2 akĩĩra nyina atĩrĩ, “Cekeri ngiri ĩmwe na igana rĩmwe cia betha iria cioirwo kuuma kũrĩ we, na iria ndaiguire ũkĩrumanĩra kĩrumi-rĩ, nĩ niĩ ndĩ nacio; nĩ niĩ ndacioire.” Nake nyina akiuga atĩrĩ, “Mũrũ wakwa, Jehova arokũrathima.”
sọ fún ìyá rẹ̀ pé, “Ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀fà ṣékélì fàdákà èyí tí wọ́n jí mọ́ ọ lọ́wọ́, àti nípa èyí tí mo gbọ́ tí ìwọ ń ṣẹ́ èpè. Kíyèsi fàdákà náà wà ní ọ̀dọ̀ mi, èmi ni mo kó o.” Nígbà náà ni ìyá rẹ̀ dáhùn pé, “Kí Olúwa bùkún ọ ọmọ mi!”
3 Rĩrĩa aacookirie cekeri icio ngiri ĩmwe na igana rĩmwe cia betha kũrĩ nyina-rĩ, nyina akiuga atĩrĩ, “Niĩ nĩndamũrĩra Jehova betha yakwa kũna nĩgeetha mũrũ wakwa athondeke mũhianano mũicũhie na mũhianano wa gũtwekio. Nĩngũgũcookeria.”
Nígbà tí ó da ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀fà ṣékélì fàdákà náà padà fún ìyá rẹ̀, ìyá rẹ̀ dáhùn pé, “Èmi ti fi òtítọ́ inú ya sílífà náà sọ́tọ̀ sí Olúwa fún ọmọ mi láti fi dá ère dídá àti ère gbígbẹ́. Èmi yóò dá a padà fún ọ.”
4 Nĩ ũndũ ũcio agĩcookia betha ĩyo kũrĩ nyina, nake nyina akĩoya cekeri magana meerĩ cia betha na agĩcineana kũrĩ mũturi wa betha, ũrĩa wacithondekire mũhianano wa gwacũhio na mũhianano wa gũtwekio. Nayo ikĩigwo thĩinĩ wa nyũmba ya Mika.
Nítorí náà òun dá sílífà náà padà fún ìyá rẹ̀, ìyá rẹ̀ sì mú igba ṣékélì fàdákà, ó sì fún alágbẹ̀dẹ fàdákà ẹni tí ó fi wọ́n rọ ère fínfín àti ère dídà. Wọ́n sì kó wọn sí ilé Mika.
5 Na rĩrĩ, mũndũ ũcio wetagwo Mika nĩ aarĩ na ihooero, nake agĩthondeka ebodi, na mĩhianano ĩmwe ya gũtwekio na agĩtua mũriũ ũmwe wake mũthĩnjĩri-ngai wake.
Ọkùnrin náà, Mika sì ní ojúbọ kan. Òun sì ra ẹ̀wù efodu kan, ó sì ṣe àwọn ère kan, ó sì fi ọ̀kan nínú àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin ṣe àlùfáà rẹ̀.
6 Matukũ-inĩ macio Isiraeli gũtiarĩ mũthamaki; o mũndũ ekaga ũrĩa oonaga kwagĩrĩire.
Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì àwọn ọmọ Israẹli kò ní ọba; olúkúlùkù ṣe bí ó ti rò pé ó tọ́ ní ojú ara rẹ́.
7 Mũlawii ũmwe mwanake kuuma itũũra rĩa Bethilehemu ya Juda, watũũraga thĩinĩ wa mũhĩrĩga wa Juda,
Ọ̀dọ́mọkùnrin kan sì ti Bẹtilẹhẹmu ti Juda wá, tí í ṣe ìdílé Juda, ẹni tí í ṣe ẹ̀yà Lefi, òun sì ṣe àtìpó níbẹ̀,
8 akiuma itũũra-inĩ rĩu agĩthiĩ gwetha kũndũ kũngĩ gwa gũtũũra. Arĩ njĩra-inĩ agĩkora nyũmba ya Mika ĩrĩa yarĩ bũrũri-inĩ ũrĩa wa irĩma wa Efiraimu.
ọkùnrin náà sì ti ìlú Bẹtilẹhẹmu ti Juda lọ, láti ṣe àtìpó ní ibikíbi tí ó bá rí. Ní ojú ọ̀nà àjò rẹ̀, ó dé ilẹ̀ Mika nínú àwọn ilẹ̀ òkè Efraimu.
9 Mika akĩmũũria atĩrĩ, “Wee uumĩte kũ?” Nake akĩmũcookeria atĩrĩ, “Niĩ ndĩ Mũlawii kuuma Bethilehemu ya Juda, na ndĩreetha kũndũ gwa gũtũũra.”
Mika bi í pé, “Níbo ni ó ti ń bọ̀?” Ó dáhùn pé, “Ọmọ Lefi ni mí láti Bẹtilẹhẹmu Juda, mo sì ń wá ibi tí èmi yóò máa gbé.”
10 Nake Mika akĩmwĩra atĩrĩ, “Tũũrania na niĩ ũtuĩke baba na mũthĩnjĩri-ngai wakwa, na nĩndĩrĩkũheaga cekeri ikũmi cia betha o mwaka, na nguo ciaku cia kwĩhumba na irio cia kũrĩa.”
Mika sì sọ fún un wí pé, “Dúró lọ́dọ̀ mi kí ìwọ sì jẹ́ baba mi àti àlùfáà fún mi, èmi ó sì máa fún ọ ní ṣékélì mẹ́wàá fàdákà ní ọdọọdún, pẹ̀lú aṣọ àti oúnjẹ rẹ̀.”
11 Nĩ ũndũ ũcio Mũlawii ũcio agĩĩtĩkĩra gũtũũrania hamwe nake, na mwanake ũcio agĩtuĩka ta ũmwe wa ariũ ake.
Ọmọ Lefi náà sì gbà láti máa bá a gbé, ọ̀dọ́mọkùnrin náà sì dàbí ọ̀kan nínú àwọn ọmọ rẹ̀.
12 Ningĩ Mika akĩamũra Mũlawii ũcio, nake mwanake ũcio agĩtuĩka mũthĩnjĩri-ngai wake na agĩtũũra gwake mũciĩ.
Nígbà náà ni Mika ya ará Lefi náà sí mímọ́, ọ̀dọ́mọkùnrin náà sì di àlùfáà rẹ̀, ó sì ń gbé ilé rẹ̀.
13 Nake Mika akiuga atĩrĩ, “Rĩu nĩndamenya atĩ Jehova nĩekũnjĩka wega, nĩgũkorwo Mũlawii ũyũ nĩatuĩkĩte mũthĩnjĩri-ngai wakwa.”
Mika sì wí pé, “Báyìí, èmi mọ̀ pé Olúwa yóò ṣe mi ní oore nítorí pé mo ní ọmọ Lefi ní àlùfáà mi.”