< Jona 1 >
1 Na rĩrĩ, ndũmĩrĩri ya Jehova nĩyakinyĩire Jona mũrũ wa Amitai, akĩĩrwo atĩrĩ:
Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Jona ọmọ Amittai wá, wí pé:
2 “Ũkĩra, ũthiĩ itũũra rĩrĩa inene rĩa Nineve, na ũrĩhunjĩrie ũkĩrĩkaanagia, nĩgũkorwo waganu warĩo nĩwambatĩte ũgakinya o harĩ niĩ.”
“Dìde lọ sí ìlú ńlá Ninefe kí o sì wàásù sí i, nítorí ìwà búburú rẹ̀ gòkè wá iwájú mi.”
3 No Jona agĩũkĩra nĩguo orĩre Jehova, akĩerekera Tarishishi. Agĩikũrũka nginya Jopa na agĩkorerera marikabu yathiiaga Tarishishi. Aarĩkia kũrĩha thogora wa rũgendo, akĩingĩra marikabu nĩguo athiĩ Tarishishi, orĩre Jehova.
Ṣùgbọ́n Jona dìde kúrò láti sálọ sí Tarṣiṣi kúrò níwájú Olúwa, ó sì sọ̀kalẹ̀ lọ sí Joppa, ìbí ti ó tí rí ọkọ̀ kan tí ń lọ sí Tarṣiṣi: lẹ́yìn ti ó sanwó ọkọ̀, ó wọlé sínú rẹ̀, láti bá wọn lọ sí Tarṣiṣi kúrò níwájú Olúwa.
4 No rĩrĩ, Jehova akĩrehe rũhuho rũnene kũu iria-inĩ, gũkĩgĩa kĩhuhũkanio kĩnene mũno, hakuhĩ marikabu ĩyo yunĩkange.
Nígbà náà ni Olúwa rán ìjì ńlá jáde sí ojú Òkun, ìjì líle sì wà nínú Òkun tó bẹ́ẹ̀ tí ọkọ̀ náà dàbí ẹni pé yóò fọ́.
5 Atwari ayo othe makĩmaka na o mũndũ agĩkaĩra ngai yake; magĩcooka magĩikia mĩrigo iria-inĩ, nĩgeetha marikabu ĩhũthe. No Jona nĩaikũrũkĩte kũu marikabu thĩinĩ, na agakoma toro mũnene.
Nígbà náà ni àwọn atukọ̀ bẹ̀rù, olúkúlùkù sì ń kígbe sí ọlọ́run rẹ̀, wọ́n kó ẹrù tí ó wà nínú ọkọ̀ dà sínú Òkun, kí ó bá à lè fúyẹ́. Ṣùgbọ́n Jona sọ̀kalẹ̀ lọ sí ìsàlẹ̀ ọkọ̀ ó sì dùbúlẹ̀, ó sùn wọra.
6 Tondũ ũcio mũnene wa marikabu agĩthiĩ harĩ we, akĩmũũria atĩrĩ, “Wee ũngĩhota gũkoma atĩa? Ũkĩra ũkaĩre ngai yaku! No gũkorwo yahota gũtũigua twage gũthira.”
Bẹ́ẹ̀ ni olórí ọkọ̀ tọ̀ ọ́ wá, ó sì wí fún un pé, “Èéṣe tí ìwọ fi sùn, ìwọ olóòórùn? Dìde kí o ké pe Ọlọ́run rẹ! Bóyá yóò ro tiwa, kí àwa má ba à ṣègbé.”
7 Ningĩ atwari a marikabu makĩĩrana atĩrĩ, “Ũkai tũcuuke mĩtĩ nĩguo tũmenye nũũ ũrehete mũtino ũyũ.” Magĩcuuka mĩtĩ naguo mũtĩ ũkĩgwĩra Jona.
Nígbà náà ni àwọn atukọ̀ sọ fún ara wọn pé, “Wá, ẹ jẹ́ kí a sẹ́ kèké, kí àwa kí o le mọ̀ nítorí ta ni búburú yìí ṣe wá sórí wa.” Wọ́n ṣẹ́ kèké, kèké sì mú Jona.
8 Nĩ ũndũ ũcio, makĩmũũria atĩrĩ, “Ta twĩre, nũũ ũtũmĩte thĩĩna ũyũ wothe ũtũkore? Wee-rĩ, ũrutaga wĩra ũrĩkũ? Uumĩte kũ? Wĩ wa bũrũri ũrĩkũ? Wĩ wa rũrĩrĩ rũrĩkũ?”
Nígbà náà ni wọn wí fún un pé, “Sọ fún wa, àwa bẹ̀ ọ́, nítorí ta ni búburú yìí ṣe wá sórí wa? Kí ni iṣẹ́ rẹ? Níbo ni ìwọ ti wá? Kí ni orúkọ ìlú rẹ? Ẹ̀yà orílẹ̀-èdè wo sì ni ìwọ sì í ṣe?”
9 Nake Jona akĩmacookeria atĩrĩ, “Niĩ ndĩ Mũhibirania na ndĩ mũhooi Jehova, Ngai wa igũrũ, ũrĩa wombire iria na thĩ nyũmũ.”
Òun sì dá wọn lóhùn pé, “Heberu ni èmi, mo sì bẹ̀rù Olúwa, Ọlọ́run ọ̀run ẹni tí ó dá Òkun àti ìyàngbẹ ilẹ̀.”
10 Ũndũ ũcio ũkĩmeekĩra guoya, makĩmũũria atĩrĩ, “Nĩ atĩa wĩkĩte?” (Nĩmamenyete atĩ nĩ kũũra ooragĩra Jehova, tondũ nĩameerĩte ũguo.)
Nígbà náà ni àwọn ọkùnrin náà bẹ̀rù gidigidi, wọn sì wí fún un pé, “Èéṣe tí ìwọ fi ṣe èyí?” (Nítorí àwọn ọkùnrin náà mọ̀ pé ó ń sá kúrò ní iwájú Olúwa ni, nítorí òun ti sọ fun wọn bẹ́ẹ̀).
11 Narĩo iria rĩgĩkĩrĩrĩria kũhuhũkania. Nĩ ũndũ ũcio makĩmũũria atĩrĩ, “Ũkwenda tũgwĩke atĩa nĩgeetha tũhoorererwo nĩ iria?”
Nígbà náà ni wọ́n wí fún un pé, “Kí ni kí àwa ó ṣe sí ọ kí Òkun lè dákẹ́ fún wa?” Nítorí Òkun ru, ó sì ja ẹ̀fúùfù líle.
12 Nake akĩmacookeria atĩrĩ, “Njoyai mũnjikie iria-inĩ na nĩrĩkũhoorera. Niĩ nĩnjũũĩ atĩ nĩ mahĩtia makwa matũmĩte kĩhuhũkanio gĩkĩ kĩnene kĩmũkore.”
Òun sì wí fún wọn pé, “Ẹ gbé mi, kí ẹ sì sọ mi sínú Òkun, bẹ́ẹ̀ ni okun yóò sì dákẹ́ fún un yin. Nítorí èmi mọ̀ pé, nítorí mi ni ẹ̀fúùfù líle yìí ṣe dé bá a yín.”
13 No andũ acio makĩĩrutanĩria mũno gũcookia marikabu yao hũgũrũrũ-inĩ cia iria. No makĩremwo, nĩgũkorwo iria nĩrĩakĩrĩrĩirie kũhuhũkania makĩria ma ũrĩa rĩarĩ mbere.
Ṣùgbọ́n àwọn ọkùnrin náà gbìyànjú gidigidi láti mú ọkọ̀ wà sí ilẹ̀, ṣùgbọ́n wọn kò lè ṣe é: nítorí tí Òkun túbọ̀ ru sí i, ó sì ja ẹ̀fúùfù líle sí wọn.
14 Nao magĩkaĩra Jehova makiuga atĩrĩ, “Twagũthaitha Wee Jehova, ndũkareke tũkue nĩ ũndũ wa muoyo wa mũndũ ũyũ. Ndũgatũcookererie mahĩtia ma kũũraga mũndũ ũtehĩtie, nĩgũkorwo Wee Jehova, wĩkĩte ũrĩa wonete arĩ wega.”
Nítorí náà wọ́n kígbe sí Olúwa, wọ́n sì wí pé, “Olúwa àwa bẹ̀ ọ́, má ṣe jẹ́ kí àwa ṣègbé nítorí ẹ̀mí ọkùnrin yìí. Má sì ka ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ sí wa ní ọrùn, nítorí ìwọ, Olúwa, ti ṣe bí ó ti wù ọ́.”
15 Makĩoya Jona makĩmũikia iria-inĩ, narĩo iria rĩu rĩahurutanaga rĩkĩhoorera.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n gbé Jona, tí wọ́n sì sọ ọ́ sínú Òkun, Òkun sì dẹ́kun ríru rẹ̀.
16 Mona ũguo andũ acio magĩĩtigĩra Jehova mũno; na makĩrutĩra Jehova igongona, na makĩĩhĩta mĩĩhĩtwa mbere yake.
Nígbà náà ni àwọn ọkùnrin náà bẹ̀rù Olúwa gidigidi, wọn si rú ẹbọ sí Olúwa, wọ́n sì jẹ́ ẹ̀jẹ́.
17 Nake Jehova agĩathĩrĩria thamaki nene mũno ĩmerie Jona, nake Jona agĩikara nda ya thamaki ĩyo matukũ matatũ, mũthenya na ũtukũ.
Ṣùgbọ́n Olúwa ti pèsè ẹja ńlá kan láti gbé Jona mì. Jona sì wà nínú ẹja náà ni ọ̀sán mẹ́ta àti òru mẹ́ta.