< Ayubu 41 >

1 “No ũhote kũguucũrũria nyamũ ĩrĩa ĩĩtagwo Leviathani na ndwano, kana wohe rũrĩmĩ rwayo na mũkanda?
“Ǹjẹ́ ìwọ le è fi ìwọ̀ fa Lefitani jáde? Tàbí ìwọ lè fi okùn so ahọ́n rẹ̀ mọ́lẹ̀?
2 No ũhote kũmĩtoonyia rũrigi iniũrũ, kana ũmĩtũrĩkanie rũthĩa na ndwano?
Ìwọ lè fi okùn bọ̀ ọ́ ní í mú, tàbí fi ìwọ̀ ẹ̀gún gun ní ẹ̀rẹ̀kẹ́?
3 No ĩtinde ĩgĩgũthaitha ũmĩiguĩre tha? No ĩkwarĩrie na ciugo cia ũhooreri?
Òun ha jẹ́ bẹ ẹ̀bẹ̀ fún àánú lọ́dọ̀ rẹ ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ bí òun ha bá ọ sọ̀rọ̀ pẹ̀lẹ́?
4 No ĩrĩkanĩre nawe ũthiĩ nayo, ĩtũũre ĩrĩ ngombo yaku nginya tene?
Òun ha bá ọ dá májẹ̀mú bí? Ìwọ ó ha máa mú ṣe ẹrú láéláé bí?
5 No ũhote kũmĩhooreria ta nyoni, kana ũmĩoherere handũ nĩguo airĩtu aku mamĩmeemagie?
Ìwọ ha lè ba sáré bí ẹni pé ẹyẹ ni, tàbí ìwọ ó dè é fún àwọn ọmọbìnrin ìránṣẹ́ rẹ̀?
6 Onjoria no mamĩkũũranie na indo ciao? No mamĩgayanie kũrĩ onjorithia?
Ẹgbẹ́ àwọn apẹja yóò ha máa tà á bí? Wọn ó ha pín láàrín àwọn oníṣòwò?
7 No ũhote gũtheecanga rũũa rwayo na mĩcengi, kana ũtheecange mũtwe wayo na mĩcengi ĩrĩa ĩtegaga thamaki?
Ìwọ ha lè fi ọ̀kọ̀-irin gun awọ rẹ̀, tàbí orí rẹ̀ pẹ̀lú ọ̀kọ̀ ìpẹja.
8 Ũngĩmĩhutia na guoko, ũngĩtũũra ũririkanaga kĩgiano kĩu, na ndũngĩgacookera!
Fi ọwọ́ rẹ lé e lára, ìwọ ó rántí ìjà náà, ìwọ kì yóò sì ṣe bẹ́ẹ̀ mọ́.
9 Mwĩrĩgĩrĩro wa atĩ no ũmĩtoorie nĩ kwĩheenia; o kũmĩona tu nĩkũiganĩte gũtũma mũndũ amake, orwo nĩ hinya.
Kíyèsi, ìgbìyànjú láti mú un ní asán; ní kìkì ìrí rẹ̀ ara kì yóò ha rọ̀ ọ́ wẹ̀sì?
10 Gũtirĩ mũndũ ũrĩ ũcamba mũiganu wa kũmĩarahũra. Nũũ ũngĩkĩhota kwĩĩndiiria niĩ?
Kò sí ẹni aláyà lílé tí ó lè ru sókè. Ǹjẹ́ ta ni ó lè dúró níwájú mi.
11 Nũũ ũngĩnandũra kĩndũ atĩ nĩguo ndĩmũrĩhe? Kĩndũ gĩothe kĩrĩ rungu rwa igũrũ nĩ gĩakwa.
Ta ni ó kọ́kọ́ ṣe fún mi, tí èmi ìbá fi san án fún un? Ohunkóhun ti ń bẹ lábẹ́ ọ̀run gbogbo, tèmi ni.
12 “Ndikwaga kwaria ũhoro wa ciĩga ciayo, o na wa hinya wayo, na wa ũthaka wayo.
“Èmi kì yóò fi ẹ̀yà ara Lefitani, tàbí ipá rẹ, tàbí ìhámọ́ra rẹ tí ó ní ẹwà pamọ́.
13 Nũũ ũngĩhota kũmĩaũra nguo yayo ya igũrũ? Nũũ ũngĩmĩkuhĩrĩria amĩĩkĩre matamu?
Ta ni yóò lè rídìí aṣọ àpáta rẹ̀? Tàbí ta ni ó lè súnmọ́ ọ̀nà méjì eyín rẹ̀?
14 Nũũ ũngĩũmĩrĩria kũmĩathamia kanua, kau kaiyũrĩte magego ma kũmakania?
Ta ni ó lè ṣí ìlẹ̀kùn iwájú rẹ̀? Àyíká ẹ̀yin rẹ ni ìbẹ̀rù ńlá.
15 Mũgongo wayo ũrĩ na ngo ciĩiganĩrĩire mĩhari, ikomanĩire ikanyiitana;
Ìpẹ́ lílé ní ìgbéraga rẹ̀; ó pàdé pọ̀ tímọ́tímọ́ bí àmì èdìdì.
16 o ĩmwe ĩnyiitanĩte na ĩrĩa ĩngĩ, ũũ atĩ gũtirĩ rĩera rĩngĩtoonyera gatagatĩ ga cio.
Èkínní fi ara mọ́ èkejì tó bẹ́ẹ̀ tí afẹ́fẹ́ kò lè wọ àárín wọn.
17 Igwatanĩtio hamwe irĩ nũmu; inyiitanĩte hamwe ũndũ itangĩtigithũkana.
Èkínní fi ara mọ́ èkejì rẹ̀; wọ́n lè wọ́n pọ̀ tí a kò lè mọ̀ wọ́n.
18 Gũtiiha kwayo kũmenũkagia ũtheri; maitho mayo nĩ ta mĩrũri ya rũciinĩ gũgĩthererũka.
Nípa sí sin rẹ̀ ìmọ́lẹ̀ á mọ́, ojú rẹ̀ a sì dàbí ìpéǹpéjú òwúrọ̀.
19 Imũrĩ cia mwaki ciumaga kanua-inĩ kayo; ĩrathũkagia thandĩ cia mwaki.
Láti ẹnu rẹ ni ọ̀wọ́-iná ti jáde wá, ìpẹ́pẹ́ iná a sì ta jáde.
20 Ĩrutaga ndogo na maniũrũ taarĩ nyũngũ ĩratherũka ĩhagĩrĩtwo igũrũ rĩa mwaki wa ithanjĩ.
Láti ihò imú rẹ ni èéfín ti jáde wá, bí ẹni pé láti inú ìkòkò tí a fẹ́ iná ìfèéfèé lábẹ́ rẹ̀.
21 Mĩhũmũ yayo ĩgwatagia makara mwaki, naruo rũrĩrĩmbĩ rũkoima kanua kayo.
Èémí rẹ̀ tiná bọ ẹ̀yin iná, ọ̀wọ́-iná sì ti ẹnu rẹ̀ jáde.
22 Ngingo-inĩ yayo nĩho hinya wayo ũkoragwo, ũrĩa ũmakagia kĩrĩa gĩothe gĩtũnganaga nayo.
Ní ọrùn rẹ̀ ní agbára kù sí, àti ìbànújẹ́ àyà sì padà di ayọ̀ níwájú rẹ̀.
23 Mĩgũtha ya nyama ciayo nĩmĩnyiitanu mũno; nĩ mĩrũmu ũũ atĩ ndĩngĩenyenyeka.
Jabajaba ẹran rẹ̀ dìjọ pọ̀, wọ́n múra gírí fún ara wọn, a kò lè sí wọn ní ipò.
24 Ngoro yayo yũmĩte ta ihiga, ĩkooma ta ihiga rĩa gũthĩa rĩa na thĩ.
Àyà rẹ̀ dúró gbagidi bí òkúta, àní, ó le bi ìyá ọlọ.
25 Rĩrĩa yarahũka, arĩa marĩ hinya nĩmamakaga; mooraga ĩtanamahũũra.
Nígbà tí ó bá gbé ara rẹ̀ sókè, àwọn alágbára bẹ̀rù; nítorí ìbẹ̀rù ńlá, wọ́n dààmú.
26 Gũtirĩ rũhiũ rwa njora rũngĩmĩĩka ũndũ, o na kana itimũ, kana mũguĩ, kana mĩcengi.
Ọ̀kọ̀ tàbí idà, tàbí ọfà, ẹni tí ó ṣá a kò lè rán an.
27 Harĩ Leviathani-rĩ, kĩgera no ta nyeki nyũmũ, nakĩo gĩcango no ta gĩcunjĩ kĩbuthu kĩa mũtĩ.
Ó ká irin sí ibi koríko gbígbẹ àti idẹ si bi igi híhù.
28 Mĩguĩ ndĩngĩtũma yũre; mahiga ma kĩgũtha no ta mũũngũ harĩ yo.
Ọfà kò lè mú un sá; òkúta kànnakánná lọ́dọ̀ rẹ̀ dàbí àgékù koríko.
29 Harĩ yo njũgũma no ta gacunjĩ ka rũnyeki rũmũ; ĩthekagĩrĩra kũbĩrĩrĩka gwa itimũ.
Ó ka ẹṣin sí bí àgékù ìdì koríko; ó rẹ́rìn-ín sí mímì ọ̀kọ̀.
30 Nda yayo nĩ ta rũgĩo rũrĩ na mageca; ĩtigaga ngururo ndaka-inĩ ta cia ngaari iria ikonyoraga ngano.
Òkúta mímú ń bẹ nísàlẹ̀ abẹ́ rẹ̀, ó sì tẹ́ ohun mímú ṣóńṣó sórí ẹrẹ̀.
31 Ĩtũmaga iria kũrĩa kũriku gũtherũke ta nyũngũ, na ĩkoiruga iria ta nyũngũ ya maguta ma kwĩhaka.
Ó mú ibú omi hó bí ìkòkò; ó sọ̀ agbami òkun dàbí kólòbó ìkunra.
32 Harĩa yagerera ĩtigaga mũhari ũkũhenia; mũndũ no eciirie atĩ ndia ĩrĩ na mbuĩ.
Ó mú ipa ọ̀nà tan lẹ́yìn rẹ̀; ènìyàn a máa ka ibú sí ewú arúgbó.
33 Gũtirĩ kĩndũ kĩngĩigananio nayo gũkũ thĩ; nĩ kĩũmbe gĩtarĩ guoya.
Lórí ilẹ̀ ayé kò sí ẹni tí ó dàbí rẹ̀, tí a dá láìní ìbẹ̀rù.
34 Ĩnyũrũragia kĩrĩa gĩothe gĩĩtũũgagĩria; nĩyo mũthamaki wa kĩrĩa gĩothe gĩĩtĩĩaga.”
Ó bojú wo ohun gíga gbogbo, ó sì nìkan jásí ọba lórí gbogbo àwọn ọmọ ìgbéraga.”

< Ayubu 41 >