< Ayubu 40 >

1 Ningĩ Jehova akĩĩra Ayubu atĩrĩ:
Olúwa dá Jobu lóhùn sí pẹ̀lú, ó sì wí pé,
2 “Mũndũ ũrĩa ũrũaga na Mwene-Hinya-Wothe-rĩ, no amũrute mahĩtia? Ũcio ũkararagia Ngai-rĩ, nĩakĩmũcookerie!”
“Ẹni tí ń bá Olódùmarè wíjọ́ yóò ha kọ ní ẹ̀kọ́? Ẹni tí ń bá Ọlọ́run wí jẹ́ kí ó dáhùn!”
3 Nake Ayubu agĩcookeria Jehova, akĩmwĩra atĩrĩ:
Nígbà náà ni Jobu dá Olúwa lóhùn wá ó sì wí pé,
4 “Niĩ ndiagĩrĩire o na hanini; ndaakĩhota atĩa gũgũcookeria? Nĩndehumbĩra kanua na guoko.
“Kíyèsi i, ẹ̀gbin ni èmi—ohun kí ni èmi ó dà? Èmi ó fi ọwọ́ mi le ẹnu mi.
5 Nĩndaririe rĩmwe, no ndirĩ na macookio; o na ngĩaria rĩa keerĩ, no ndirĩ na ũndũ ũngĩ nguuga.”
Ẹ̀ẹ̀kan ní mo sọ̀rọ̀, ṣùgbọ́n èmi kì yóò tún sọ mọ́; lẹ́ẹ̀kejì ni, èmi kò sì le ṣe é mọ́.”
6 Ningĩ Jehova akĩarĩria Ayubu arĩ kĩhuhũkanio-inĩ, akĩmwĩra atĩrĩ:
Nígbà náà ní Olúwa dá Jobu lóhùn láti inú ìjì àyíká wá, ó sì wí pé,
7 “Wĩhotore ta mũndũ mũrũme; nĩngũkũũria ciũria, nawe ũkĩnjookerie.
“Di àmùrè gírí ní ẹgbẹ́ rẹ bí ọkùnrin, èmi ó bi ọ léèrè, kí ìwọ kí ó sì dá mi lóhùn.
8 “Gũtua ciira gwakwa na kĩhooto-rĩ, githĩ no ũkũmenererie? Githĩ no ũndue mwĩhia nĩgeetha wee ũtuĩke ndwĩhĩtie?
“Ìwọ ha fẹ́ mú ìdájọ́ mi di asán? Ìwọ ó sì dá mi lẹ́bi, kí ìwọ lè ṣe olódodo.
9 Wee-rĩ, ũrĩ na guoko ta kwa Mũrungu? Wee wahota kũruruma na mũgambo ta wake?
Ìwọ ni apá bí Ọlọ́run tàbí ìwọ lè fi ohùn sán àrá bí òun?
10 Ta kĩĩgemie na riiri na ũkengi, na wĩhumbe gĩtĩĩo na ũnene.
Fi ọláńlá àti ọlá ìtayọ rẹ̀ ṣe ara rẹ ní ọ̀ṣọ́, tí ó sì fi ògo àti títóbi ọ̀ṣọ́ bo ara ní aṣọ.
11 Rekereria marakara mahiũ ma mangʼũrĩ maku, wone mũndũ o wothe mwĩtĩĩi ũmũharũrũkie,
Mú ìrunú ìbínú rẹ jáde; kíyèsí gbogbo ìwà ìgbéraga rẹ kí o sì rẹ̀ ẹ́ sílẹ̀.
12 rora mũndũ o wothe mwĩtĩĩi na ũmũnyiihie, ũmemende andũ arĩa aaganu o harĩa marũngiĩ.
Wo gbogbo ìwà ìgbéraga, ènìyàn kí o sì rẹ ẹ sílẹ̀ kí o sì tẹ ènìyàn búburú mọ́lẹ̀ ní ipò wọn.
13 Mathike othe hamwe tĩĩri-inĩ; ũmoohe mothiũ na nduma kũu mbĩrĩra-inĩ.
Sin gbogbo wọn papọ̀ nínú erùpẹ̀, kí o sì di ojú ìkọ̀kọ̀ wọn ní isà òkú.
14 Hĩndĩ ĩyo niĩ mwene nĩngetĩkania nawe atĩ guoko gwaku mwene kwa ũrĩo no gũkũhonokie.
Nígbà náà ní èmi ó yìn ọ́ pé, ọwọ́ ọ̀tún ara rẹ lè gbà ọ́ là.
15 “Ta rora nyamũ ĩrĩa ĩtagwo Behemothu, ĩyo ndoombire hamwe nawe, na ĩrĩĩaga nyeki ta ndegwa.
“Ǹjẹ́ nísinsin yìí kíyèsi Behemoti, tí mo dá pẹ̀lú rẹ, òun a máa jẹ koríko bí ọ̀dá màlúù.
16 Nĩ hinya ũigana atĩa ĩrĩ naguo njohero, na nĩ ũhoti mũnene atĩa ũrĩ mĩkiha-inĩ yayo ya nda!
Wò o nísinsin yìí, agbára rẹ wà ní ẹ̀gbẹ́ rẹ, àti ipa rẹ nínú ìṣàn ìkún rẹ.
17 Ĩinagia mũtingʼoe wayo ta mũtarakwa; nga cia ciero ciayo ciohanĩtio hamwe ta mĩhĩndo.
Òun a máa jù ìrù rẹ̀ bí i igi kedari, iṣan itan rẹ̀ dìjọ pọ̀.
18 Mahĩndĩ mayo mahaana ta mĩberethi ya gĩcango, nacio ciĩga ciayo cihaana ta irungʼo cia kĩgera.
Egungun rẹ̀ ní ògùṣọ̀ idẹ, Egungun rẹ̀ dàbí ọ̀pá irin.
19 Nĩyo nyamũ ya mbere harĩ ciũmbe cia Mũrungu, no rĩrĩ, Mũũmbi wayo nowe ũngĩmĩkuhĩrĩria na rũhiũ rwake rwa njora.
Òun ni olórí nínú àwọn iṣẹ́ Ọlọ́run; síbẹ̀ Ẹlẹ́dàá rẹ̀ fi idà rẹ̀ lé e lọ́wọ́.
20 Irĩma ĩmĩheaga maciaro maacio, na nyamũ ciothe cia gĩthaka itũũhagĩra gũkuhĩ na kũu.
Nítòótọ́ òkè ńlá ńlá ní i mu ohun jíjẹ fún un wá, níbi tí gbogbo ẹranko igbó máa ṣiré ní ẹ̀gbẹ́ ibẹ̀.
21 Ĩkomaga rungu rwa mahũa ma maaĩ-inĩ, ĩĩhithĩte thĩinĩ wa ithanjĩ kũrĩa kũrĩ mũtondo.
Ó dùbúlẹ̀ lábẹ́ igi lótusì, lábẹ́ eèsún àti ẹrẹ̀.
22 Mahũa macio ma maaĩ-inĩ makamĩhitha; nakĩo kĩĩruru kĩa mĩtĩ ya irura hũgũrũrũ-inĩ cia karũũĩ gĩkamĩthiũrũrũkĩria.
Igi lótusì síji wọn bò o; igi arọrọ odò yí i káàkiri.
23 Rĩrĩa rũũĩ ruoka na nditi, ndĩmakaga; nĩngitĩre, o na Rũũĩ rwa Jorodani rũngĩmĩiyũrĩrĩra nginya kanua.
Kíyèsi i, odò ńlá sàn jọjọ, òun kò sálọ; ó wà láìléwu bí ó bá ṣe pé odò Jordani ti ṣàn lọ sí ẹnu rẹ̀.
24 Kũrĩ mũndũ ũngĩhota kũmĩnyiita rĩrĩa ĩĩhũũgĩte, kana amĩtege, amĩtũrĩkie iniũrũ na amĩĩkĩre kĩana kĩa rũrigi?
Ẹnìkan ha lè mú un ní ojú rẹ̀, tàbí dẹkùn fún tàbí a máa fi ọ̀kọ̀ gún imú rẹ̀?

< Ayubu 40 >