< Ayubu 37 >
1 “Ndaigua ũguo ngoro yakwa ĩgatumatuuma, na ĩkambarara ĩkoima handũ hayo.
“Àyà sì fò mi sí èyí pẹ̀lú, ó sì kúrò ní ipò rẹ̀.
2 Thikĩrĩria! Thikĩrĩria mũraramo wa mũgambo wake, mũrurumo ũrĩa uumaga kanua gake.
Fetísílẹ̀! Fetísílẹ̀, kí ẹ sì gbọ́ ìró ohùn rẹ̀, àti èyí tí ó ti ẹnu rẹ̀ jáde wá.
3 Arekagĩrĩria rũheni rwake rungu rwa igũrũ guothe na akarũtũma nginya ituri cia thĩ.
Ó ṣe ìlànà rẹ̀ ní ìsàlẹ̀ ọ̀run gbogbo, mọ̀nàmọ́ná rẹ̀ ni ó sì jọ̀wọ́ rẹ̀ lọ́wọ́ dé òpin ilẹ̀ ayé.
4 Thuutha waruo gũũkaga mũgambo wa mũraramo wake; arurumaga na mũgambo wake mũkaru. Hĩndĩ ĩrĩa mũgambo wake waiguuo-rĩ, ndarigagĩrĩria heni.
Lẹ́yìn mọ̀nàmọ́ná ohùn kan fọ̀ ramúramù; ó sì fi ohùn ọláńlá rẹ̀ sán àrá. Òhun kì yóò sì dá àrá dúró, nígbà tí ó bá ń gbọ́ ohùn rẹ̀.
5 Mũgambo wa Mũrungu ũrurumaga na njĩra ya magegania; ekaga maũndũ manene tũtangĩhota kũmenya.
Ọlọ́run fi ohùn rẹ̀ sán àrá ní ọ̀nà ìyanu; ohùn ńlá ńlá ni í ṣe tí àwa kò le mọ̀.
6 Eeraga tharunji atĩrĩ, ‘Gwa thĩ,’ nayo mbura ya rũthuthuũ akamĩĩra atĩrĩ, ‘Tuĩka mbura nene.’
Nítorí tí ó wí fún yìnyín pé, ‘Ìwọ rọ̀ sílẹ̀ ayé,’ àti pẹ̀lú fún ọwọ́ òjò, ‘Fún òjò ńlá agbára rẹ̀.’
7 Nĩatigithagia mũndũ o wothe wĩra wake nĩgeetha andũ othe ombĩte mamenye wĩra wake.
Ó fi èdìdì di ọwọ́ gbogbo ènìyàn kí gbogbo wọn kí ó lè mọ iṣẹ́ rẹ̀, ó sì tún dá olúkúlùkù ènìyàn dúró lẹ́nu iṣẹ́ rẹ̀.
8 Nyamũ nacio nĩciĩhithaga; ciikaraga imamo-inĩ ciacio.
Nígbà náà ní àwọn ẹranko wọ inú ihò lọ, wọn a sì wà ni ipò wọn.
9 Kĩhuhũkanio kiumaga gĩikaro gĩakĩo, heho nayo ĩkoima rũhuho-inĩ rũkĩhurutana.
Láti ìhà gúúsù ni ìjì àjàyíká tí jáde wá, àti òtútù láti inú afẹ́fẹ́ ti tú àwọsánmọ̀ ká.
10 Mĩhũmũ ya Mũrungu nĩĩthondekaga mbarabu, namo maaĩ harĩa maaramĩire makanyiitana.
Nípa ẹ̀mí Ọlọ́run a fi ìdí omi fún ni, ibú omi á sì súnkì.
11 Nĩaiyũragia matu na ũigũ; ahurunjaga rũheni rũkamatũrĩkia.
Pẹ̀lúpẹ̀lú ó fi omi púpọ̀ mú àwọsánmọ̀ wúwo, a sì tú àwọsánmọ̀ ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ ká ara wọn.
12 Mathiiaga magĩthiũrũrũkaga o kũrĩa angĩmeerekeria thĩ yothe, mageeke o ũrĩa wothe angĩmaatha.
Àwọn wọ̀nyí yí káàkiri nípa ìlànà rẹ̀, kí wọn kí ó lè ṣe ohunkóhun tí ó pàṣẹ fún wọn lórí ilẹ̀ ayé.
13 Arehaga matu macio nĩguo aherithie andũ, kana aihũgie thĩ yake na onanie wendani wake.
Ó mú àwọsánmọ̀ wá, ìbá ṣe fún ìkìlọ̀, tàbí omi wá sí ayé láti fi ìfẹ́ rẹ̀ hàn.
14 “Ayubu, thikĩrĩria ũhoro ũyũ; tithĩria hau wĩcũũranie ũhoro wa magegania ma Mũrungu.
“Jobu, dẹtí sílẹ̀ sí èyí; dúró jẹ́ẹ́ kí o sì ro iṣẹ́ ìyanu Ọlọ́run.
15 Wee nĩũũĩ ũrĩa Ngai aathaga matu, na ũrĩa atũmaga rũheni rwake rũhenũke?
Ṣe ìwọ mọ àkókò ìgbà tí Ọlọ́run ṣe wọ́n lọ́jọ̀, tí ó sì mú ìmọ́lẹ̀ àwọsánmọ̀ rẹ̀ dán?
16 Wee nĩũũĩ ũrĩa matu macio macuurĩtio wega, magegania macio ma ũrĩa ũrĩ ũmenyo mũkinyanĩru?
Ṣé ìwọ mọ ìgbà tí àwọsánmọ̀ í fò lọ, iṣẹ́ ìyanu ẹni tí ó pé ní ìmọ̀?
17 Wee ũringĩkaga nĩ ũrugarĩ wa nguo ciaku rĩrĩa bũrũri ũkirĩte ki hĩndĩ ya rũhuho rwa gũthini-rĩ,
Ìwọ ẹni ti aṣọ rẹ̀ ti máa n gbóná, nígbà tí ó fi atẹ́gùn ìhà gúúsù mú ayé dákẹ́.
18 no ũhote kũruta wĩra nake ũhoro-inĩ wa gũtambũrũkia matu mairũ, o macio momĩte o ta gĩcicio gĩa gĩcango?
Ìwọ ha ba tẹ́ pẹpẹ ojú ọ̀run, tí ó dúró ṣinṣin, tí ó sì dàbí dígí tí ó yọ̀ dà?
19 “Ta twĩre ũrĩa twagĩrĩirwo nĩ kũmwĩra; tũtingĩhota gwĩciirĩra nĩ ũndũ wa nduma iitũ.
“Kọ́ wa ní èyí tí a lè wí fún un; nítorí pé àwa kò le wádìí ọ̀rọ̀ náà nítorí òkùnkùn wa.
20 Nĩagĩrĩire kwĩrwo atĩ nĩngwenda kwaria? Nĩ kũrĩ mũndũ o na ũ ũngiuga amerio?
A ó ha wí fún un pé, èmi fẹ́ sọ̀rọ̀? Tàbí ẹnìkan lè wí pé, ìfẹ́ mi ni pé kí a gbé mi mì?
21 Rĩu-rĩ, gũtirĩ mũndũ ũngĩhota kũrora riũa, rĩcangararĩte kũu igũrũ thuutha wakuo kũhaatwo nĩ rũhuho gũgathera.
Síbẹ̀ nísinsin yìí ènìyàn kò rí oòrùn tí ń dán nínú àwọsánmọ̀, ṣùgbọ́n afẹ́fẹ́ ń kọjá, a sì gbá wọn mọ́.
22 Okaga kuuma mwena wa gathigathini arĩ na riiri ukengeete ta wa thahabu; Ngai okaga arĩ na ũkaru wa gwĩtigĩrwo.
Wúrà dídán ti inú ìhà àríwá jáde wá; lọ́dọ̀ Ọlọ́run ni ọláńlá ẹ̀rù ńlá wa.
23 Ũcio Mwene-Hinya-Wothe-rĩ, tũtingĩhota kũmũkinyĩra, nĩatũũgĩrĩtio nĩ ũndũ wa ũhoti wake; tondũ wa ũrĩa arĩ wa kĩhooto na ũthingu mũnene-rĩ, ndahinyanagĩrĩria.
Nípa ti Olódùmarè àwa kò le wádìí rẹ̀, ó rékọjá ní ipá; nínú ìdájọ́ àti títí bi òun kì í ba ẹ̀tọ́ àti ọ̀pọ̀lọpọ̀ òtítọ́ jẹ́.
24 Nĩ ũndũ ũcio andũ nĩmamũtĩĩte, tondũ githĩ ndarũmbũyagia arĩa meyonaga ta marĩ oogĩ na ngoro ciao?”
Nítorí náà ènìyàn ha máa bẹ̀rù rẹ̀, òun kì í ṣe ojú sájú ẹnikẹ́ni tí ó gbọ́n ní ayé?”