< Ayubu 35 >

1 Ningĩ Elihu akiuga atĩrĩ:
Elihu sì wí pe:
2 “Nĩũgwĩciiria ũhoro ũyũ nĩ wa kĩhooto? Ũroiga atĩrĩ, ‘Mũrungu nĩekũnjarĩrĩria atue ndiĩhĩtie.’
“Ìwọ rò pé èyí ha tọ́, tí ìwọ wí pé, òdodo mi ni èyí níwájú Ọlọ́run?
3 No rĩrĩ, wee no ũramũũria atĩrĩ, ‘Kũrĩ na uumithio ũrĩkũ harĩ niĩ, na ngũgunĩka nakĩ ndaaga kwĩhia?’
Nítorí tí ìwọ wí pé èrè kí ní yóò jásí fún ọ, tàbí èrè kí ni èmi yóò fi jẹ́ ju èrè ẹ̀ṣẹ̀ mi lọ.
4 “No nyende gũgũcookeria ũhoro, wee hamwe na arata aku.
“Èmi ó dá ọ lóhùn àti àwọn ẹgbẹ́ rẹ pẹ̀lú rẹ.
5 Ta rora igũrũ wone; ta cũthĩrĩria matu macio marĩ igũrũ rĩaku kũraya mũno.
Síjú wo ọ̀run; kí o rí i, kí ó sì bojú wo àwọsánmọ̀ tí ó ga jù ọ́ lọ.
6 Ũngĩĩhia-rĩ, ũndũ ũcio ũngĩhutia Ngai atĩa? Mehia maku mangĩingĩha mũno-rĩ, ũndũ ũcio ũngĩmwĩka atĩa?
Bí ìwọ bá dẹ́ṣẹ̀, kí ni ìwọ fi sẹ̀ sí? Tàbí bí ìrékọjá rẹ di púpọ̀, kí ni ìwọ fi èyí nì ṣe sí i?
7 Ũngĩkorwo ũrĩ mũthingu-rĩ, ũngĩmũhe kĩĩ, kana nĩ kĩĩ aamũkagĩra kuuma guoko-inĩ gwaku?
Bí ìwọ bá sì ṣe olódodo, kí ni ìwọ fi fún un, tàbí kí ni òun rí gbà láti ọwọ́ rẹ wá?
8 Waganu waku ũhutagia o mũndũ tawe, na ũthingu waku ũkahutia o ciana cia andũ.
Ìwà búburú rẹ ni fún ènìyàn bí ìwọ; òdodo rẹ sì ni fún ọmọ ènìyàn.
9 “Andũ makayaga nĩ icooki rĩa kũhinyĩrĩrio; mathaithanaga mateithũrwo guoko-inĩ kwa ũcio ũrĩ hinya mũingĩ.
“Nípa ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìninilára, wọ́n mú ni kígbe; wọ́n kígbe nípa apá àwọn alágbára.
10 No gũtirĩ mũndũ uugaga atĩrĩ, ‘Ngai ũrĩa wanyũũmbire arĩ ha, ũrĩa ũheaga mũndũ nyĩmbo ũtukũ,
Ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí ó wí pé, ‘Níbo ni Ọlọ́run Ẹlẹ́dàá mi wà tí ó sì fi orin fún mi ní òru;
11 ũrĩa ũtũrutaga maũndũ gũkĩra ũrĩa arutaga nyamũ cia werũ-inĩ, o na agatũhe ũũgĩ gũkĩra nyoni cia rĩera-inĩ?’
tí òun kọ́ wa ní ẹ̀kọ́ jù àwọn ẹranko ayé lọ, tí ó sì mú wa gbọ́n ju àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run lọ?’
12 Ndacookagia rĩrĩa andũ maakaya nĩ ũndũ wa mwĩtũũgĩrio wa andũ arĩa aaganu.
Nígbà náà ni wọ́n ń ké ṣùgbọ́n Ọlọ́run kò dáhùn nítorí ìgbéraga ènìyàn búburú.
13 Ti-itherũ, Mũrungu ndathikagĩrĩria mathaithana mao ma tũhũ; ũcio Mwene-Hinya-Wothe ndarũmbũyagia mathaithana macio.
Nítòótọ́ Ọlọ́run kì yóò gbọ́ ọ̀rọ̀ asán; bẹ́ẹ̀ ní Olódùmarè kì yóò kà á sí.
14 Githĩ ndakaaga gũthikĩrĩria mũno makĩria rĩrĩa ũkuuga atĩ ndũramuona, na atĩ ciira waku ũrĩ mbere yake, na no nginya ũmweterere,
Bí ó tilẹ̀ ṣe pé ìwọ wí pé ìwọ kì í rí i, ọ̀rọ̀ ìdájọ́ ń bẹ níwájú rẹ, ẹni tí ìwọ sì gbọdọ̀ dúró dè.
15 na makĩria ma ũguo ũkoiga atĩ marakara make matiherithanagia na ndarũmbũyagia waganu o na hanini!
Ṣùgbọ́n nísinsin yìí nítorí tí ìbínú rẹ̀ kò tí fìyà jẹ ni, òun kò ni ka ìwà búburú si?
16 Nĩ ũndũ ũcio Ayubu atumũrĩte kanua gake akaaria ũhoro wa tũhũ; nĩarĩĩtie ndeto nyingĩ atarĩ na ũmenyo.”
Nítorí náà ní Jobu ṣe ya ẹnu rẹ̀ lásán ó sọ ọ̀rọ̀ di púpọ̀ láìsí ìmọ̀.”

< Ayubu 35 >