< Ayubu 31 >

1 “Niĩ nĩtwarĩĩkanĩire na maitho makwa ndikanarore mũirĩtu ndĩmwĩrirĩrie.
“Mo ti bá ojú mi dá májẹ̀mú, èmi yó ha ṣe tẹjúmọ́ wúńdíá?
2 Nĩ ũndũ-rĩ, kaĩ rũgai rwa mũndũ kuuma igũrũ kwa Ngai rũkĩrĩ kĩĩ? Igai rĩake nĩ rĩrĩkũ kuuma kũrĩ ũcio Mwene-Hinya-Wothe ũrĩ igũrũ?
Nítorí pé kí ni ìpín Ọlọ́run láti ọ̀run wá? Tàbí kí ni ogún Olódùmarè láti òkè ọ̀run wá.
3 Githĩ ti kwanangwo kwa arĩa aaganu, na mũtino kũrĩ arĩa meekaga maũndũ mooru?
Kò ṣe pé àwọn ènìyàn búburú ni ìparun wà fún, àti àjàkálẹ̀-ààrùn fún àwọn oníṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀?
4 Githĩ we ndonaga njĩra ciakwa, na agatara o ikinya o ikinya rĩakwa?
Òun kò ha ri ipa ọ̀nà mi, òun kò ha sì ka gbogbo ìṣísẹ̀ mi?
5 “Ingĩkorwo thiiaga na njĩra itarĩ cia ma-rĩ, kana kũgũrũ gwakwa gũkahiũha thiĩ ngaheenanie-rĩ,
“Bí ó bá ṣe pé èmi bá fi àìṣòótọ́ rìn, tàbí tí ẹsẹ̀ mi sì yára sí ẹ̀tàn,
6 Ngai nĩathime na ratiri cia kĩhooto, nake nĩekũmenya atĩ niĩ ndirĩ ũcuuke;
(jẹ́ kí Ọlọ́run wọ́n mí nínú ìwọ̀n òdodo, kí Ọlọ́run le mọ ìdúró ṣinṣin mi.)
7 makinya makwa mangĩkorwo nĩmahũkĩte makoima njĩra-inĩ, nayo ngoro yakwa ĩngĩkorwo nĩĩtongoretio nĩ maitho makwa, kana moko makwa makorwo nĩmathaahĩtio-rĩ,
Bí ẹsẹ̀ mí bá yà kúrò lójú ọ̀nà, tí àyà mí sì tẹ̀lé ipa ojú mi, tàbí bí àbàwọ́n kan bá sì lẹ̀ mọ́ mi ní ọwọ́,
8 hĩndĩ ĩyo kĩrĩa haandĩte kĩrorĩĩo nĩ andũ angĩ, nacio irio cia mĩgũnda yakwa iromunywo.
ǹjẹ́ kí èmi kí ó gbìn kí ẹlòmíràn kí ó sì mújẹ, àní kí a fa irú-ọmọ mi tu.
9 “Ngoro yakwa ĩngĩkorwo yanaheenererio nĩ mũndũ-wa-nja, kana ngorwo ndanaceema mũrango-inĩ wa mũndũ wa itũũra,
“Bí àyà mi bá di fífà sí ipasẹ̀ obìnrin kan, tàbí bí mo bá lọ í ba de ènìyàn ní ẹnu-ọ̀nà ilé aládùúgbò mi,
10 hĩndĩ ĩyo mũtumia wakwa arothĩa ngano ya mũndũ ũngĩ, na arũme angĩ tiga niĩ marokoma nake.
kí àyà mi kí ó lọ ọlọ fún ẹlòmíràn, kí àwọn ẹlòmíràn kí ó tẹ̀ ara wọn ní ara rẹ̀.
11 Nĩgũkorwo ũndũ ũcio nĩ ũmaramari wa thoni, na nĩ rĩĩhia rĩa gũtuĩrwo ciira nĩ kĩama.
Nítorí pé yóò jẹ́ ohun ìtìjú àní, ẹ̀ṣẹ̀ tí a ó ṣe onídàájọ́ rẹ̀.
12 Tondũ ũcio nĩ mwaki ũrĩa ũcinaga nginya ũkaananga; na nĩũngĩamunyĩte magetha makwa mothe.
Nítorí pé iná ní èyí tí ó jó dé ibi ìparun, tí ìbá sì fa gbòǹgbò ohun ìbísí mi gbogbo tu.
13 “Ingĩkorwo nĩnyimĩte ndungata ciakwa cia arũme na cia andũ-a-nja kĩhooto rĩrĩa manateta nĩ ũndũ wakwa-rĩ,
“Tí mo bá sì ṣe àìka ọ̀ràn ìránṣẹ́kùnrin mi tàbí ìránṣẹ́bìnrin mi sí, nígbà tí wọ́n bá ń bá mi jà;
14 niĩ ngeeka atĩa rĩrĩa Mũrungu akaanjũkĩrĩra? Ngaacookia atĩa rĩrĩa ngeetwo ndĩĩtetere ũhoro-inĩ ũcio?
kí ni èmi ó ha ṣe nígbà tí Ọlọ́run bá dìde? Nígbà tí ó bá sì ṣe ìbẹ̀wò, ohùn kí ni èmi ó dá?
15 Githĩ ũcio wanyũũmbire kũu nda ya maitũ to we wamoombire? Githĩ tiwe watũthondekire tũrĩ kũu nda cia aa maitũ?
Ẹni tí ó dá mi ní inú kọ́ ni ó dá a? Ẹnìkan náà kí ó mọ wá ní inú ìyá wa?
16 “Ingĩkorwo ndanaima athĩĩni kĩrĩa maanerirĩria, kana ngareka maitho ma mũtũmia wa ndigwa morwo nĩ hinya-rĩ,
“Bí mo bá fa ọwọ́ sẹ́yìn fún ìfẹ́ inú tálákà, tàbí bí mo bá sì mú kí ojú opó rẹ̀wẹ̀sì,
17 ingĩkorwo ndĩĩaga irio ciakwa nyiki, ngaaga kũgayana na ũrĩa ũtarĩ ithe-rĩ,
tàbí tí mo bá nìkan bu òkèlè mi jẹ, tí aláìní baba kò jẹ nínú rẹ̀;
18 (no niĩ kuuma ũnini wakwa, mwana ta ũcio ndaamũreraga o ta ũrĩa angĩarerirwo nĩ ithe, na kuuma gũciarwo gwakwa ndũire ndongoragia mũtumia wa ndigwa)
nítorí pé láti ìgbà èwe mi wá ni a ti tọ́ ọ dàgbà pẹ̀lú mi bí ẹni pé baba, èmi sì ń ṣe ìtọ́jú opó láti inú ìyá mi wá:
19 ingĩkorwo ndanoona mũndũ agĩkua nĩ ũndũ wa kwaga nguo, kana ngoona mũndũ mũbatari atarĩ kĩndũ gĩa kwĩhumba,
bí èmi bá rí olùpọ́njú láìní aṣọ, tàbí tálákà kan láìní ìbora;
20 na ngoro yake ndĩandathimire nĩ ũndũ wa kũmũiguithia ũrugarĩ na guoya wa ngʼondu ciakwa-rĩ,
bí ọkàn rẹ̀ kò bá súre fún mi, tàbí bí ara rẹ̀ kò sì gbóná nípasẹ̀ irun àgùntàn mi;
21 ingĩkorwo ndanoya guoko gwakwa ngookĩrĩra mwana ũtarĩ ithe, nĩkũmenya atĩ no nyone wa kũndeithia kwagĩa ciira igooti-inĩ-rĩ,
bí mo bá sì gbé ọwọ́ mi sókè sí aláìní baba, nítorí pé mo rí ìrànlọ́wọ́ mi ní ẹnu ibodè,
22 hĩndĩ ĩyo guoko gwakwa kũroahũkĩra kĩande-inĩ kũgwe, kũroinĩkĩra o irũngo-inĩ.
ǹjẹ́, ní apá mi kí o wọ́n kúrò ní ihò èjìká rẹ̀, kí apá mi kí ó sì ṣẹ́ láti egungun rẹ̀ wá.
23 Nĩ ũndũ nĩndetigagĩra mwanangĩko uumĩte kũrĩ Mũrungu, na nĩ ũndũ wa gwĩtigĩra riiri wake, ndingĩekire maũndũ ta macio.
Nítorí pé ìparun láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá ni ẹ̀rù ńlá fún mi, àti nítorí ọláńlá rẹ̀ èmi kò le è dúró.
24 “Ingĩkorwo nĩnjigĩte mwĩhoko wakwa harĩ thahabu, kana ngeera thahabu ĩrĩa therie mũno atĩrĩ, ‘Wee nĩwe ũgitĩri wakwa,’
“Bí ó bá ṣe pé mo fi wúrà ṣe ìgbẹ́kẹ̀lé mi, tàbí tí mo bá wí fún fàdákà dídára pé, ‘Ìwọ ni ààbò mi,’
25 ingĩkorwo ndanakenera ũtonga wakwa mũnene, kana ngakenera uumithio ũrĩa moko makwa mecarĩirie-rĩ,
bí mo bá yọ̀ nítorí ọrọ̀ mí pọ̀, àti nítorí ọwọ́ mi dara lọ́pọ̀lọ́pọ̀,
26 ingĩkorwo ndanarũmbũiya riũa rĩarĩte, kana mweri ũgĩthiĩ ũcangararĩte,
bí mo bá bojú wo oòrùn nígbà tí ń ràn, tàbí òṣùpá tí ń ràn nínú ìtànmọ́lẹ̀,
27 na ngoro yakwa ĩkĩheenererio nĩcio na hitho, kana guoko gwakwa gũgĩcikinyĩria kĩmumunyano gĩa gũcitĩĩa-rĩ,
bí a bá tàn ọkàn mi jẹ láti fi ẹnu mi kò ọwọ́ mi,
28 o na macio mangĩtuĩka mehia ma gũtuĩrwo ciira, nĩgũkorwo ingĩtuĩkĩte mũndũ ũtarĩ mwĩhokeku harĩ Mũrungu ũrĩa ũrĩ igũrũ.
èyí pẹ̀lú ni ẹ̀ṣẹ̀ ti àwọn onídàájọ́ ní láti bẹ̀wò, nítorí pé èmí yóò jẹ́ aláìṣòótọ́ sí Ọlọ́run tí ó wà lókè.
29 “Ingĩkorwo ndaanakena nĩ thũ yakwa kuona mũtino, kana ngĩmĩthekerera rĩrĩa thĩĩna wamĩkora,
“Bí ó bá ṣe pé mo yọ̀ sì ìparun ẹni tí ó kórìíra mi. Tàbí bí mo bá sì gbéraga sókè, nígbà tí ibi bá a.
30 no niĩ ndirĩ ndetĩkĩra kanua gakwa keehie na ũndũ wa kũhoera muoyo wayo kĩrumi,
Bẹ́ẹ̀ èmi kò sì jẹ ki ẹnu mi ki ó ṣẹ̀ nípa fífẹ́ ègún sí ọkàn rẹ̀.
31 kũngĩkorwo andũ a nyũmba yakwa matirĩ moiga atĩrĩ, ‘Nũũ ũtarĩ warĩa nyama cia Ayubu akahũũna?’
Bí àwọn ènìyàn inú àgọ́ mi kò bá lè wí pé, ‘Ta ni kò ì tí ì jẹ ẹran rẹ̀ ní àjẹyó?’
32 no gũtirĩ mũgeni wanaraara njĩra-inĩ, nĩ ũndũ mũrango wa mũciĩ wakwa ũtũire ũhingũrĩirwo mũgendi,
Àlejò kò wọ̀ ni ìgboro rí; èmí ṣí ìlẹ̀kùn mi sílẹ̀ fún èrò.
33 ingĩkorwo ndaanahitha mehia makwa, ta ũrĩa andũ meekaga, na ũndũ wa kũhitha mahĩtia ngoro-inĩ yakwa
Bí mo bá bò ẹ̀ṣẹ̀ mi mọ́lẹ̀ bí Adamu ni pápá, ẹ̀bi mi pamọ́ ni àyà mi.
34 tondũ wa gwĩtigĩra kĩrĩndĩ, o na gwĩtigĩra kũmenwo nĩ mĩhĩrĩga ngagĩkira ki na ndiume nja-rĩ,
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni mo ha bẹ̀rù bí? Tàbí ẹ̀gàn àwọn ìdílé ní ń bà mí ní ẹ̀rù? Tí mo fi pa ẹnu mọ́, tí èmí kò sì fi sọ̀rọ̀ jáde?
35 (“Naarĩ korwo ndaarĩ na mũndũ wa kũnjigua! Rĩu nĩndekĩra rũũri rwa kwĩyarĩrĩria: reke Mwene-Hinya-Wothe anjookerie ũhoro; reke mũũthitangi andĩke marũa ma thitango yake.
(“Ìbá ṣe pé ẹnìkan le gbọ́ ti èmí! Kíyèsi i, àmì mi, kí Olódùmarè kí ó dá mi lóhùn, kí èmí kí ó sì rí ìwé náà tí olùfisùn mi ti kọ.
36 Ti-itherũ marũa macio ingĩmaigĩrĩra kĩande, ndĩmehumbe taarĩ thũmbĩ.
Nítòótọ́ èmí ìbá gbé le èjìká mi, èmi ìbá sì dé bí adé mọ́ orí mi.
37 Njooke ndĩmũhe ũhoro wakwa ikinya gwa ikinya; ndĩmũkuhĩrĩrie ta ndĩ mũnene.)
Èmi ìbá sì sọ iye ìṣísẹ̀ mi fún un, bí ọmọ-aládé ni èmi ìbá súnmọ́ ọ̀dọ̀ rẹ̀.)
38 “Korwo mũgũnda wakwa wakaya, ũnjũkĩrĩre, nayo mĩtaro yaguo yothe ĩkorwo ĩkĩrĩra maithori,
“Bí ilẹ̀ mi bá sì ké rara lòdì sí mi tí a sì fi omijé kún gbogbo poro rẹ̀.
39 ingĩkorwo ndanarĩa maciaro maguo iteekũrĩha, kana ngoraga ngoro cia ene guo-rĩ,
Bí mo bá jẹ èso oko mi láìsan owó tàbí tí mo sì mú ọkàn olúwa rẹ̀ fò lọ,
40 hĩndĩ ĩyo congʼe ũrokũra kuo handũ ha ngano, na riya handũ ha cairi.” Ndeto cia Ayubu nĩciathira.
kí ẹ̀gún òṣùṣú kí ó hù dípò alikama, àti èpò búburú dípò ọkà barle.” Ọ̀rọ̀ Jobu parí.

< Ayubu 31 >