< Ayubu 19 >
1 Nake Ayubu akĩũria atĩrĩ:
Ìgbà náà ni Jobu dáhùn, ó sì wí pé:
2 “Mũkũũnyariira nginya-rĩ, mũkĩĩhehenjaga na ciugo?
“Yóò ti pẹ́ tó tí ẹ̀yin ó fi máa fi ìyà jẹ mí, tí ẹ̀yin ó fi máa fi ọ̀rọ̀ yìí?
3 Rĩu mũrĩ kũndetia maita ikũmi; mũũtharĩkĩire mũtarĩ na thoni.
Ìgbà mẹ́wàá ní yin yọ mi lénu ẹ̀yin ti ń gàn mí; ojú kò tì yín tí ẹ fi jẹ mí ní yà.
4 Angĩkorwo nĩ ma atĩ nĩhĩtĩtie njĩra, ihĩtia rĩakwa rĩgũikara rĩrĩ thĩĩna wakwa.
Kí a sì wí bẹ́ẹ̀ pé, mo ṣìnà nítòótọ́, ìṣìnà mi wà lára èmi tìkára mi.
5 Mũngĩkorwo ti-itherũ nĩmũgwĩtũũgĩria igũrũ rĩakwa, na mũgĩe na mweke wa kũnjũkĩrĩra nĩ ũndũ wa ũguo njonorithĩtio,
Bí ó tilẹ̀ ṣe pé ẹ̀yin ó ṣògo si mi lórí nítòótọ́, tí ẹ ó sì máa fi ẹ̀gàn mi gún mí lójú,
6 no kĩmenyei atĩ Ngai nĩwe ũũhĩtĩirie, akandigiicĩria na wabu wake.
kí ẹ mọ̀ nísinsin yìí pé, Ọlọ́run ni ó bì mí ṣubú, ó sì nà àwọ̀n rẹ̀ yí mi ká.
7 “O na gũtuĩka nĩngayaga ngoiga atĩrĩ, ‘Ndĩĩmũhĩtĩrie!’ Niĩ ndirĩ ũndũ njookagĩrio; o na gũtuĩka nĩhooyaga ndeithio, gũtirĩ kĩhooto nyonaga.
“Kíyèsi, èmi ń kígbe pe, ‘Ọwọ́ alágbára!’ Ṣùgbọ́n a kò gbọ́ ti èmi; mo kígbe fún ìrànlọ́wọ́, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ìdájọ́.
8 Nĩahingĩire njĩra na niĩ ndingĩhota kũhĩtũka; tũcĩra twakwa nĩatwĩkĩrĩte nduma.
Ó ṣọgbà dí ọ̀nà mi tí èmi kò le è kọjá, Ó sì mú òkùnkùn ṣú sí ipa ọ̀nà mi.
9 Nĩanjaũrĩte gĩtĩĩo gĩakwa, na akanduta thũmbĩ mũtwe.
Ó ti bọ́ ògo mi, ó sì ṣí adé kúrò ní orí mi.
10 Andarũrangaga kuuma mbarĩ ciothe nginya ngathira; amunyaga mwĩhoko wakwa o ta mũtĩ.
Ó ti bà mí jẹ́ ní ìhà gbogbo, ẹ̀mí sì pin; ìrètí mi ni a ó sì fàtu bí igi.
11 Marakara make nĩmanjakanĩire; andaraga hamwe na thũ ciake.
Ó sì tiná bọ ìbínú rẹ̀ sí mi, ó sì kà mí sí bí ọ̀kan nínú àwọn ọ̀tá rẹ̀.
12 Mbũtũ ciake cia ita injerekagĩra na hinya; ciakaga ihumbu cia kũnjũkĩrĩra, igathiũrũrũkĩria hema yakwa.
Ẹgbẹ́ ogun rẹ̀ sì dàpọ̀ sí mi, wọ́n sì mọ odi yí mi ká, wọ́n sì yí àgọ́ mi ká.
13 “Nĩanyamũranĩtie na ariũ a baba makaahutatĩra; andũ arĩa tũyaine nao nĩmeĩndigithĩtie biũ.
“Ó mú àwọn arákùnrin mi jìnà sí mi réré, àti àwọn ojúlùmọ̀ mi di àjèjì sí mi pátápátá.
14 Andũ a mbarĩ ciitũ nĩmathiĩte makandiga; arata akwa nĩmariganĩirwo nĩ niĩ.
Àwọn alájọbí mi fàsẹ́yìn, àwọn ọ̀rẹ́ tímọ́tímọ́ mi sì di onígbàgbé mi.
15 Ageni akwa na ndungata ciakwa cia andũ-a-nja matuaga ta matanjũũĩ; maanyonaga ta ndĩ mũndũ uumĩte kũndũ kũngĩ.
Àwọn ará inú ilé mi àti àwọn ìránṣẹ́bìnrin mi kà mí sí àjèjì; èmi jásí àjèjì ènìyàn ní ojú wọn.
16 Njĩtaga ndungata yakwa, no ndĩngĩnjĩtĩka, o na ndĩmĩthaithĩte na kanua gakwa niĩ mwene.
Mo pe ìránṣẹ́ mi, òun kò sì dá mi lóhùn; mo fi ẹnu mi bẹ̀ ẹ́.
17 Mĩhũmũ ya kanua gakwa nĩmĩnungu harĩ mũtumia wakwa; nduĩkĩte wa kũmenwo harĩ ariũ a maitũ.
Ẹ̀mí mi ṣú àyà mi, àti òórùn mi ṣú àwọn ọmọ inú ìyá mi.
18 O na tũhĩĩ tũrĩa tũnini nĩtũũnyararĩte, rĩrĩa ndatuumĩrĩra no gũũthekerera tũũthekagĩrĩra.
Àní àwọn ọmọdékùnrin fi mí ṣẹ̀sín, mo dìde, wọ́n sì sọ̀rọ̀ ẹ̀gàn sí mi.
19 Arata akwa arĩa manguhĩrĩirie othe nĩmathũire; andũ arĩa nyendeete nĩmahutatĩire makaanjũkĩrĩra.
Gbogbo àwọn ọ̀rẹ́ kòríkòsùn mi kórìíra mi, àwọn olùfẹ́ mi sì kẹ̀yìndà mí.
20 Niĩ thirĩte ngatigara o gĩkonde na mahĩndĩ; niĩ ndigarĩirwo no kĩni kĩa magego giiki.
Egungun mi lẹ̀ mọ́ ara mi àti mọ́ ẹran-ara mi, mo sì yọ́ pẹ̀lú awọ eyín mi.
21 “Njiguĩrai tha, inyuĩ arata akwa, iguai tha, nĩgũkorwo guoko kwa Ngai nĩkũngũthĩte.
“Ẹ ṣàánú fún mi, ẹ ṣàánú fún mi, ẹ̀yin ọ̀rẹ́ mi, nítorí ọwọ́ Ọlọ́run ti bà mí.
22 Mũthingatanaga na niĩ o ta ũrĩa Mũrungu aathingataga nĩkĩ? Mũtirĩ mũraiganwo nĩ nyama ciakwa?
Nítorí kí ni ẹ̀yin ṣe lépa mi bí Ọlọ́run, tí ẹran-ara mi kò tẹ́ yín lọ́rùn?
23 “Naarĩ korwo ciugo ciakwa nĩciandĩkĩtwo, igakĩandĩkwo ibuku-inĩ rĩa gĩkũnjo,
“Háà! Ìbá ṣe pé a le kọ̀wé ọ̀rọ̀ mi nísinsin yìí, ìbá ṣe pé a le kọ ọ sínú ìwé!
24 igakarwo na karamu ga kĩgera igũrũ rĩa ngocorai, kana igakururwo rwaro-inĩ rwa ihiga itũũre nginya tene!
Kí a fi kálámù irin àti ti òjé kọ wọ́n sínú àpáta fún láéláé.
25 Nĩnjũũĩ atĩ Mũngũũri arĩ muoyo, na atĩ marigĩrĩrio-inĩ nĩwe ũkaarũgama thĩ ĩno.
Nítorí èmi mọ̀ pé olùdáǹdè mi ń bẹ láààyè àti pe òun ni yóò dìde dúró lórí ilẹ̀ ní ìkẹyìn;
26 Nakĩo gĩkonde gĩkĩ gĩakwa kĩarĩkia gũthira, na mwĩrĩ ũyũ wa nyama ũkorwo ũtarĩ ho, hĩndĩ ĩyo nĩ ngoona Ngai;
àti lẹ́yìn ìgbà tí a pa àwọ̀ ara mi run, síbẹ̀ láìsí ẹran-ara mi ni èmi ó rí Ọlọ́run,
27 niĩ mwene nĩngamwĩonera na maitho, niĩ mwene, ti mũndũ ũngĩ. Ĩ ngoro yakwa ndĩkĩrĩ na wendo mũnene!
ẹni tí èmi ó rí fún ara mi, tí ojú mi ó sì wo, kì sì í ṣe ti ẹlòmíràn; ọkàn mi sì dákú ní inú mi.
28 “Mũngiuga atĩrĩ, ‘Ĩ nĩtũthingatane nake, kuona atĩ nĩwe kĩhumo gĩa thĩĩna ũyũ,’
“Bí ẹ̀yin bá wí pé, ‘Àwa ó ti lépa rẹ̀ tó! Àti pé, gbogbo ọ̀rọ̀ náà ni a sá à rí ní ọwọ́ rẹ̀,’
29 inyuĩ ene nĩmwagĩrĩirwo nĩ gwĩtigĩra rũhiũ rwa njora; nĩgũkorwo mangʼũrĩ nĩmakarehithia kũherithanio na rũhiũ rwa njora, na hĩndĩ ĩyo nĩmũkamenya atĩ nĩ kũrĩ ũtuanĩri wa ciira.”
kí ẹ̀yin kí ó bẹ̀rù, nítorí ìbínú ní í mú ìjìyà wá nípa idà, kí ẹ̀yin kí ó lè mọ̀ pé ìdájọ́ kan ń bẹ.”