< Jeremia 6 >

1 “Mwĩtharei mwĩhonokie, inyuĩ andũ a Benjamini! Mwĩtharei muume Jerusalemu! Huhai karumbeta mũrĩ kũu Tekoa! Ĩkĩrai kĩmenyithia kũu Bethi-Hakeremu! Nĩgũkorwo ũũru nĩũũkĩte uumĩte na mwena wa gathigathini, na nĩ ũũru wa kũniinanwo kũnene mũno.
“Ẹ̀yin ènìyàn Benjamini, sá sí ibi ààbò! Ẹ sá kúrò ní Jerusalẹmu. Ẹ fọn fèrè ní Tekoa! Kí ẹ gbé àmì sókè lórí Beti-Hakeremu! Nítorí àjálù farahàn láti àríwá, àní ìparun tí ó lágbára.
2 Nĩngananga Mwarĩ wa Zayuni, o ũcio mũthaka na mwĩbacĩrĩri mũno.
Èmi yóò pa ọmọbìnrin Sioni run, tí ó jẹ́ arẹwà àti ẹlẹgẹ́.
3 Arĩithi marĩ na ndũũru ciao cia mbũri nĩmagooka nĩguo mamũũkĩrĩre; nĩmakaamba hema ciao imũthiũrũrũkĩirie mĩena yothe, o mũndũ o mũndũ akarangĩra handũ hake.”
Olùṣọ́-àgùntàn pẹ̀lú agbo wọn yóò gbóguntì wọ́n. Wọn yóò pa àgọ́ yí wọn ká, olúkúlùkù yóò máa jẹ ní ilé rẹ̀.”
4 “Mwĩhaarĩriei tũrũe nake! Arahũkai, rekei tũmũtharĩkĩre mĩaraho! No rĩrĩ, wũi-ĩiya-ĩ! Nĩkũratuka, nacio ciĩruru cia hwaĩ-inĩ nĩiraraiha.
“Ẹ ya ará yín sí mímọ́ láti bá a jagun! Dìde, kí a kọlù ú ní ìgbà ọ̀sán! Ṣùgbọ́n ó ṣe, nítorí ọjọ́ lọ tán, ọjọ́ alẹ́ náà sì gùn sí i.
5 Nĩ ũndũ ũcio, arahũkai, tũtharĩkĩre kũrĩ ũtukũ, tũharaganie ciĩgitio ciake iria nũmu!”
Nítorí náà, ẹ dìde, ẹ jẹ́ kí a kọlù ú ní àṣálẹ́ kí a sì ba odi alágbára rẹ̀ jẹ́.”
6 Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga atĩrĩ: “Temai mĩtĩ mũmĩige ihũba nene ingʼetheire Jerusalemu. Itũũra rĩrĩ inene no nginya rĩherithio; nĩ ũndũ rĩiyũrĩte ũhoro wa kũhinyanĩrĩria.
Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Àwọn ọmọ-ogun wí: “Ẹ ké àwọn igi náà lulẹ̀ kí ẹ sì mọ odi ààbò yí Jerusalẹmu ká. Èyí ni ìlú títóbi tí a ó bẹ̀wò, nítorí pé ó kún fún ìninilára.
7 O ta ũrĩa gĩthima gĩtherũkaga maaĩ-rĩ, ũguo noguo itũũra rĩu rĩtherũkaga waganu. Maũndũ ma ũhinya na wanangi no mo maiguagwo kuo; ndwari ciakuo na nguraro nĩcio ndũũraga nyonaga.
Gẹ́gẹ́ bí kànga ṣe ń da omi inú rẹ̀ sílẹ̀, náà ni ó ń tú ìwà búburú rẹ̀ jáde. Ìwà ipá àti ìparun ń tún pariwo nínú rẹ̀; nígbà gbogbo ni àìsàn àti ọgbẹ́ rẹ̀ ń wà níwájú mi.
8 Atĩrĩrĩ, wee Jerusalemu, ĩtĩkĩra gũtaarwo, kwaga ũguo nĩngũkũhutatĩra na ndũme bũrũri waku ũkire ihooru, nginya kwage mũndũ ũngĩtũũra kuo.”
Ìwọ Jerusalẹmu, gba ìkìlọ̀, kí Èmi kí ó má ba à lọ kúrò ní ọ̀dọ̀ rẹ, kí n sì sọ ilẹ̀ rẹ di ahoro, tí kò ní ní olùgbé.”
9 Ũũ nĩguo Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga: “Atĩrĩrĩ, andũ nĩmarekwo mahaare matigari ma Isiraeli mahinyĩtie, o ta ũrĩa mũthabibũ ũhaaragwo; cookerithia guoko honge-inĩ rĩngĩ, o ta ũrĩa mũcookereria wa thabibũ ekaga.”
Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Jẹ́ kí wọn pèsè ìyókù Israẹli ní tónítóní bí àjàrà; na ọwọ́ rẹ sí àwọn ẹ̀ka nì lẹ́ẹ̀kan sí i gẹ́gẹ́ bí ẹnìkan ti í kó èso àjàrà jọ.”
10 Nũũ ingĩkĩarĩria ndĩmũkaanie na anjigue? Nũũ ũngĩĩthikĩrĩria? Matũ mao nĩmahinge, nĩ ũndũ ũcio matiingĩigua. Ndũmĩrĩri ya Jehova nĩĩmahĩtagĩria, na matingĩmĩkenera.
Ta ni ẹni tí mo lè bá sọ̀rọ̀ àti tí mo lè fún ní ìmọ̀ràn? Ta ni yóò tẹ́tí sílẹ̀ sí mi? Etí wọn ti di, nítorí náà wọn kò lè gbọ́. Ọ̀rọ̀ Olúwa, jẹ́ ohun búburú sí wọn, wọn kò sì ní inú dídùn nínú rẹ̀.
11 No rĩrĩ, niĩ njiyũrĩtwo nĩ mangʼũrĩ ma Jehova, ndingĩhota kũmahingĩrĩria. “Maitĩrĩrie ciana iria irĩ barabara-inĩ, na ũmaitĩrĩrie aanake arĩa monganĩte hamwe; mũthuuri na mũtumia wake, maitĩkĩrwo nĩmo, o ũndũ ũmwe na andũ arĩa akũrũ, arĩa maingĩhĩtie mĩaka.
Èmi kún fún ìbínú Olúwa, èmi kò sì le è pa á mọ́ra. “Tú u sí orí àwọn ọmọ ńigboro, àti sórí àwọn ọmọkùnrin tí wọn kó ra wọn jọ pọ̀, àti ọkọ àti aya ni a ò mú sínú rẹ̀, àti àwọn arúgbó tí ó ní ọjọ́ kíkún lórí.
12 Nyũmba ciao igaatuĩka cia andũ angĩ, o hamwe na mĩgũnda yao na atumia ao, rĩrĩa ngaatambũrũkia guoko gwakwa njũkĩrĩre andũ arĩa matũũraga bũrũri ũcio,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
Ilé wọn o sì di ti ẹlòmíràn, oko wọn àti àwọn aya wọn, nígbà tí èmi bá na ọwọ́ mi sí àwọn olùgbé ilẹ̀ náà,” ni Olúwa wí.
13 “Kuuma ũrĩa mũnini nginya ũrĩa mũnene, othe nĩmakoroketio nĩ kwenda kwĩguna; anabii o hamwe na athĩnjĩri-Ngai, othe nĩmaheenanagia.
“Láti orí ẹni tí ó kéré sí orí ẹni tí ó tóbi ju, gbogbo wọn ni ó sì ní ojúkòkòrò fún èrè, àwọn wòlíì àti àlùfáà lápapọ̀ sì kún fún ẹ̀tàn.
14 Mohaga kĩronda kĩa andũ akwa taarĩ kĩronda kĩa andũ matagurarĩtio mũno, makĩmeeraga atĩrĩ: ‘Gwĩ thayũ, gwĩ thayũ,’ o rĩrĩa gũtarĩ thayũ.
Wọ́n sì ń wo ọgbẹ́ àwọn ènìyàn mi bí ẹni pé kò tó nǹkan. Wọ́n ń wí pé, ‘Àlàáfíà, Àlàáfíà,’ nígbà tí kò sì sí àlàáfíà.
15 Hihi nĩmaconokaga nĩ mũtugo ũcio wao ũrĩ magigi? Aca, maticonokaga o na hanini; o na matirĩ rũkobe. Nĩ ũndũ ũcio o nao makaagũanĩra na arĩa makaagũa; nĩmakarũndwo rĩrĩa ngaamaherithia,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
Ojú ha a tì wọ́n nítorí ìwà ìríra wọn bí? Rárá, wọn kò ní ìtìjú mọ́, wọn kò tilẹ̀ ní oorun ìtìjú. Nítorí náà, wọn ó ṣubú láàrín àwọn tó ṣubú, a ó sì ké wọn lulẹ̀ nígbà tí mo bá bẹ̀ wọ́n wò,” ni Olúwa wí.
16 Jehova ekuuga atĩrĩ: “Rũgamai magomano-inĩ ma njĩra, mũtuĩrie ũhoro; ũrĩrĩriai njĩra iria ciageragwo tene, mũũrie harĩa njĩra ĩrĩa njega ĩrĩ, nĩguo mũmĩgerere, nacio ngoro cianyu nĩikahurũka. No inyuĩ mũkiuga atĩrĩ, ‘Ithuĩ tũtikũmĩgerera.’
Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “Ẹ dúró sí ìkóríta, kí ẹ sì wò, ẹ béèrè fún ọ̀nà àtijọ́, ẹ béèrè ọ̀nà dáradára nì, kí ẹ rìn nínú rẹ, ẹ̀yin yóò sì rí ìsinmi fún ọkàn yín. Ṣùgbọ́n ẹ̀yin wí pé, ‘Àwa kì yóò rìn nínú rẹ̀.’
17 Nĩndaigire arangĩri nĩguo mamũrangĩre, ngiuga atĩrĩ, ‘Ta thikĩrĩriai karumbeta!’ No inyuĩ mũkiuga atĩrĩ, ‘Ithuĩ tũtigũthikĩrĩria.’
Èmi yan olùṣọ́ fún un yín, mo sì wí pé: ‘Tẹ́tí sí dídún fèrè náà,’ ẹ̀yìn wí pé, ‘Àwa kì yóò tẹ́tí sílẹ̀.’
18 Nĩ ũndũ ũcio, thikĩrĩriai inyuĩ ndũrĩrĩ; rorai wega inyuĩ aira, nĩguo mũmenye ũrĩa gũgekĩka kũrĩ andũ akwa.
Nítorí náà, gbọ́ ẹ̀yin orílẹ̀-èdè; kíyèsi, kí ẹ sì jẹ́ ẹlẹ́rìí, ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ sí wọn.
19 Ta thikĩrĩria, wee thĩ: nĩngũrehere andũ aya mwanangĩko, ũrĩ maciaro ma maũndũ marĩa mathugundaga, tondũ nĩmagĩte gũthikĩrĩria ndũmĩrĩri yakwa, na nĩmaregete watho wakwa.
Gbọ́, ìwọ ayé! Mò ń mú ìparun bọ̀ sórí àwọn ènìyàn wọ̀nyí, èso ìrò inú wọn, nítorí wọn kò fi etí sí ọ̀rọ̀ mi, wọ́n sì ti kọ òfin mi sílẹ̀.
20 Ngĩrĩ na bata ũrĩkũ na ũbumba ũcio wa kuuma Sheba, kana igwa cia mũrĩo cia kuuma bũrũri wa kũraya? Maruta manyu ma njino matingĩĩtĩkĩrĩka; magongona manyu matingenagia.”
Èrè wo ni ó wà fún mi nínú tùràrí láti Ṣeba wá, tàbí èso dáradára láti ilẹ̀ jíjìn réré? Ẹbọ sísun yín kò ṣe ìtẹ́wọ́gbà, ọrẹ yín kò sì wù mí.”
21 Nĩ ũndũ ũcio, Jehova ekuuga atĩrĩ: “Nĩngwĩkĩra mĩhĩnga mbere ya andũ aya. Maithe na ariũ ao nĩmakahĩngagwo nĩyo; andũ a itũũra hamwe na arata ao nĩmagakua.”
Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa wí: “Èmi yóò gbé ohun ìdènà síwájú àwọn ènìyàn wọ̀nyí. Àwọn baba àti ọmọ yóò jùmọ̀ ṣubú lù wọ́n, àwọn aládùúgbò àti ọ̀rẹ́ yóò ṣègbé.”
22 Jehova ekuuga atĩrĩ: “Ta rorai muone, nĩ harĩ na ita rĩroka riumĩte bũrũri wa mwena wa gathigathini; rũrĩrĩ rũnene nĩ rwarahũrĩtwo kuuma ituri-inĩ cia thĩ.
Báyìí ni Olúwa wí: “Wò ó, àwọn ọmọ-ogun ń bọ̀ wá láti ilẹ̀ àríwá, a ó sì gbé orílẹ̀-èdè ńlá dìde láti òpin ayé wá.
23 Manyiitĩte mĩguĩ na matimũ; nĩ andũ ooru matarĩ tha. Mũrurumo wao magĩũka mahaicĩte mbarathi, nĩ ta wa ndiihũ cia iria rĩrĩa inene; maroka mehaarĩirie ta andũ moka mbaara nĩguo magũtharĩkĩre, wee Mwarĩ wa Zayuni.”
Wọ́n sì dìmọ́ra pẹ̀lú ọrun àti ọ̀kọ̀, wọ́n jẹ́ ẹni ibi, wọn kò sì ní àánú. Wọ́n ń hó bí omi Òkun, bí wọ́n ti ṣe ń gun àwọn ẹṣin wọn lọ; wọ́n sì wá bí ọkùnrin tí yóò jà ọ́ lógun, ìwọ ọmọbìnrin Sioni.”
24 Nĩtũiguĩte ũhoro wa andũ acio, namo moko maitũ nĩmorĩtwo nĩ hinya. Nĩtũnyiitĩtwo nĩ ruo rũnene, ruo rũhaana ta rwa mũtumia ũkũrũmwo.
Àwa ti gbọ́ ìròyìn nípa wọn, ọwọ́ wa sì di rírọ, ìrora sì mú wa bí obìnrin tí ń rọbí.
25 Mũtikoimagare mũthiĩ mĩgũnda, kana mũthiĩ na njĩra, nĩ ũndũ thũ ĩyo ĩrĩ na rũhiũ rwa njora, na kũrĩ na imakania irigiicĩirie mĩena yothe.
Má ṣe jáde lọ sí orí pápá tàbí kí o máa rìn ní àwọn ojú ọ̀nà, nítorí ọ̀tá náà ní idà, ìpayà sì wà níbi gbogbo.
26 Inyuĩ andũ akwa, mwĩhumbei nguo ya ikũnia, na mwĩgaragarie mũhu-inĩ; rĩrai na kĩgi, ta ũrĩa mwana wa mũmwe arĩragĩrwo, nĩgũkorwo mwanangi ũcio agaatũhithũkĩra o rĩmwe.
Ẹ̀yin ènìyàn mi, ẹ gbé aṣọ ọ̀fọ̀ wọ̀, kí ẹ sì sùn nínú eérú, ẹ ṣọ̀fọ̀ pẹ̀lú ìpohùnréré ẹkún gẹ́gẹ́ bí i lórí ọmọkùnrin yín kan ṣoṣo nítorí pé lójijì ni àwọn apanirun yóò kọlù wá.
27 “Wee nawe nĩngũtuĩte mũgeria wa cuuma, nao andũ akwa matariĩ ta kĩgera, nĩguo wee ũrorage na ũthimage mĩthiĩre yao.
“Èmi ti fi ẹ́ ṣe ẹni tí yóò máa yọ́ irú àwọn ènìyàn mi gẹ́gẹ́ bi irin tútù, kí wọn kí ó lè ṣe àkíyèsí, kí ó sì dán ọ̀nà wọn wò.
28 Nĩ aremi momĩtie ngoro, mathiiaga magĩcambanagia. Mahaana o ta gĩcango na kĩgera; othe mekaga maũndũ mathũku mũno.
Ọlọ́tẹ̀ tí ọkàn rẹ̀ le ní gbogbo wọn. Wọ́n ń lọ káàkiri láti sọ̀rọ̀-òdì. Wọ́n jẹ́ idẹ àti irin, wọ́n sì kún fún ìwà ìbàjẹ́.
29 Ihuruti nĩirahurutĩra mwaki na hinya nĩguo ũcine ngocorai, no rĩrĩ, wĩra ũcio ũrarutwo wa kũmatheria no wa tũhũ; arĩa aaganu matirathera.
Ewìrì a fẹ́ná kíkankíkan, kí ó lè yọ́ òjé, ẹni tí ń yọ́ ọ ń yọ́ ọ lásán; a kò si ya ènìyàn búburú kúrò.
30 Andũ acio marĩĩtagwo betha-ĩrĩa-ĩregetwo, nĩ ũndũ Jehova nĩamaregeete.”
A pè wọ́n ní fàdákà tí a kọ̀sílẹ̀, nítorí Olúwa ti kọ̀ wọ́n sílẹ̀.”

< Jeremia 6 >