< Jeremia 43 >

1 Rĩrĩa Jeremia aarĩkirie kũhe andũ acio ndũmĩrĩri ya Jehova Ngai wao, ũhoro ũrĩa wothe Jehova aamũtũmĩte akameere-rĩ,
Nígbà tí Jeremiah parí sísọ ọ̀rọ̀ tí Olúwa Ọlọ́run rán an sí wọn tan.
2 Azaria mũrũ wa Hoshaia, na Johanani mũrũ wa Karea, marĩ hamwe na andũ othe arĩa etĩĩi, makĩĩra Jeremia atĩrĩ, “Wee nĩũraheenania! Jehova Ngai witũ ndagũtũmĩte ũũke ũtwĩre atĩrĩ, ‘Mũtikanathiĩ bũrũri wa Misiri gũtũũra kuo.’
Asariah ọmọ Hoṣaiah àti Johanani ọmọ Karea, àti gbogbo àwọn agbéraga ọkùnrin sọ fún Jeremiah pé, “Ìwọ ń pa irọ́! Olúwa Ọlọ́run wa kò rán ọ láti sọ pé, ‘Ẹ má lọ sí Ejibiti láti ṣàtìpó níbẹ̀.’
3 No rĩrĩ, Baruku mũrũ wa Neria nĩwe ũkũringĩrĩirie ũtũũkĩrĩre, nĩguo tũneanwo kũrĩ andũ a Babuloni, nĩguo matũũrage, kana matũtahe, matũtware Babuloni.”
Ṣùgbọ́n Baruku, ọmọ Neriah, ni ó fi ọ̀rọ̀ sí ọ lẹ́nu sí wa, láti fà wá lé àwọn ará Babeli lọ́wọ́, láti pa wá àti láti kó wa ní ìgbèkùn lọ sí Babeli.”
4 Nĩ ũndũ ũcio Johanani mũrũ wa Karea marĩ hamwe na anene othe a mbũtũ cia ita, o na andũ othe, makĩrega gwathĩkĩra watho wa Jehova wa gũikara kũu bũrũri wa Juda.
Nítorí náà, Johanani ti Karea àti gbogbo àwọn olórí ogun, àti gbogbo àwọn ènìyàn tàpá sí àṣẹ Olúwa nípa dídúró sí Juda.
5 Handũ ha ũguo, Johanani mũrũ wa Karea hamwe na anene othe a mbũtũ cia ita magĩtongoria matigari mothe ma andũ a Juda, o acio macookete nĩguo maikare kũu bũrũri wa Juda moimĩte ndũrĩrĩ-inĩ ciothe kũrĩa mahurunjĩtwo.
Dípò bẹ́ẹ̀, Johanani ọmọ Karea àti gbogbo àwọn olórí ogun sì ko àwọn àjẹkù Juda tí wọ́n wá láti gbé ilẹ̀ Juda láti orílẹ̀-èdè gbogbo tí wọ́n ti tú wọn ká.
6 Ningĩ magĩtongoria arũme othe, na andũ-a-nja na ciana, o na airĩtu a mũthamaki acio Nebuzaradani mũnene wa arangĩri a mũthamaki aatigĩire Gedalia mũrũ wa Ahikamu, mũrũ wa Shafani, o na magĩtongoria Jeremia ũcio mũnabii, na Baruku mũrũ wa Neria.
Wọ́n tún kó àwọn ọkùnrin, àwọn obìnrin àti àwọn ọmọdé, àti àwọn ọmọ ọba tí ó jẹ́ obìnrin èyí tí Nebusaradani balógun ẹ̀ṣọ́ ti fi sílẹ̀ pẹ̀lú Gedaliah ọmọ Ahikamu, ọmọ Ṣafani, àti Jeremiah wòlíì náà àti Baruku ọmọ Neriah.
7 Nĩ ũndũ ũcio magĩthiĩ bũrũri wa Misiri, makĩremera Jehova, na magĩthiĩ o nginya Tahapanahesi.
Nítorí náà, wọn wọ Ejibiti pẹ̀lú àìgbọ́ràn sí àṣẹ Olúwa, wọ́n sì lọ títí dé Tafanesi.
8 Na marĩ kũu Tahapanahesi, ndũmĩrĩri ya Jehova ĩgĩkinyĩra Jeremia, akĩĩrwo atĩrĩ:
Ní Tafanesi ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah wá:
9 “Oya mahiga manene na guoko gwaku, Ayahudi makwĩroreire, ũthiĩ ũmathike na rĩũmba hau nja haarĩtwo maturubarĩ itoonyero-inĩ rĩa nyũmba ya Firaũni kũu Tahapanahesi.
“Nígbà tí àwọn Júù ń wòye mú àwọn òkúta pẹ̀lú rẹ, kí o sì rì wọ́n mọ́ inú amọ̀ tí ó wà nínú bíríkì tí ó wà níbi pèpéle ẹnu-ọ̀nà ààfin Farao ní Tafanesi.
10 Hĩndĩ ĩyo ũmeere atĩrĩ, ‘Ũũ nĩguo Jehova Mwene-Hinya-Wothe, Ngai wa Isiraeli, ekuuga: Nĩngũtũmanĩra ndungata yakwa Nebukadinezaru mũthamaki wa Babuloni, na nĩngahaanda gĩtĩ gĩake kĩa ũthamaki igũrũ rĩa mahiga maya ndathika haha; nĩakamba hema yake ya ũnene igũrũ rĩamo.
Báyìí kí o sì sọ fún wọn pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli wí. Èmi yóò ránṣẹ́ sí ìránṣẹ́ mi Nebukadnessari ọba Babeli, Èmi yóò gbé ìjọba rẹ̀ ka orí àwọn òkúta; èyí tí mo ti rì sí ibí yìí, yóò tan ìjọba rẹ̀ jù wọ́n lọ.
11 Nĩagooka atharĩkĩre bũrũri wa Misiri, oragithie andũ arĩa maathĩrĩirio gũkua, na atũme arĩa maathĩrĩirio gũtahwo matahwo, nao arĩa maathĩrĩirio kũũragwo na rũhiũ rwa njora mooragwo naruo.
Yóò gbé ogun sí Ejibiti; yóò mú ikú bá àwọn tí ó yan ikú; ìgbèkùn fún àwọn tí ó ti yan ìgbèkùn, àti idà fún àwọn tí ó yan idà.
12 Nĩagacina hekarũ cia ngai cia Misiri; agaacina hekarũ ciao na atahe ngai ciao. O ta ũrĩa mũrĩithi ehumbaga nguo yake, noguo akehumba bũrũri wa Misiri, acooke oime kuo atarĩ mũhutie.
Yóò dá, iná sun tẹmpili àwọn òrìṣà Ejibiti, yóò sun tẹmpili àwọn òrìṣà Ejibiti, yóò sì mú wọn lọ ìgbèkùn. Gẹ́gẹ́ bí olùṣọ́-àgùntàn, yóò ró aṣọ rẹ̀ mọ́ra, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni yóò ró Ejibiti òun yóò sì lọ kúrò níbẹ̀ ní àlàáfíà.
13 Nĩakoinanga itugĩ iria ihooyagwo, iria irĩ thĩinĩ wa hekarũ ya riũa kũu bũrũri wa Misiri, na acooke acine hekarũ cia ngai cia bũrũri wa Misiri ithire.’”
Ní tẹmpili ni yóò ti fọ́ ère ilé oòrùn tí ó wà ní ilẹ̀ Ejibiti túútúú, yóò sì sun àwọn tẹmpili àwọn òrìṣà Ejibiti.’”

< Jeremia 43 >