< Jeremia 18 >

1 Ĩno nĩyo ndũmĩrĩri ĩrĩa yakinyĩrĩire Jeremia yumĩte harĩ Jehova, akĩĩrwo atĩrĩ:
Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó tọ Jeremiah wá wí pe:
2 “Ikũrũka ũthiĩ nyũmba-inĩ ya mũũmbi wa nyũngũ, na wakinya kũu nĩkuo ngũkũheera ndũmĩrĩri yakwa.”
“Sọ̀kalẹ̀ lọ sí ilé amọ̀kòkò, níbẹ̀ ni èmi yóò ti bá ọ sọ̀rọ̀.”
3 Nĩ ũndũ ũcio ngĩikũrũka ngĩthiĩ kũu nyũmba-inĩ ya mũũmbi wa nyũngũ, ngĩkora akĩruta wĩra na ngaari yake ya kũũmba nyũngũ.
Nígbà náà ni mo lọ sí ilé amọ̀kòkò mo sì rí i tí ó ń ṣiṣẹ́ kan lórí kẹ̀kẹ́.
4 No rĩrĩ, nyũngũ ĩrĩa ombaga na rĩũmba nĩyathũkire ĩrĩ o moko-inĩ make; nĩ ũndũ ũcio mũũmbi ũcio agĩcooka akĩũmba nyũngũ ĩngĩ na rĩũmba o rĩu, akĩmĩthondeka o ta ũrĩa onire yagĩrĩire gũthondekwo.
Ṣùgbọ́n ìkòkò tí ó ń mọ láti ara amọ̀ bàjẹ́ ní ọwọ́ rẹ̀, nítorí náà ni amọ̀kòkò fi ṣe ìkòkò mìíràn, ó mọ ọ́n bí èyí tí ó dára jù ní ojú rẹ̀.
5 Hĩndĩ ĩyo ndũmĩrĩri ya Jehova ĩkĩnginyĩrĩra, ngĩĩrwo atĩrĩ:
Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá pé:
6 “Inyuĩ andũ a nyũmba ya Isiraeli, githĩ to njĩke na inyuĩ o ta ũrĩa mũũmbi ũyũ wa nyũngũ ekaga?” Ũguo nĩguo Jehova ekuuga. “O ta rĩũmba rĩrĩ guoko-inĩ kwa mũũmbi-rĩ, ũguo nĩguo mũtariĩ mũrĩ guoko-inĩ gwakwa, inyuĩ andũ aya a nyũmba ya Isiraeli.
“Ẹyin ilé Israẹli, èmi kò ha lè ṣe fún un yín gẹ́gẹ́ bí amọ̀kòkò yìí ti ṣe?” ni Olúwa wí. “Gẹ́gẹ́ bí amọ̀ ní ọwọ́ amọ̀kòkò bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin rí ní ọwọ́ mi, ẹ̀yin ilé Israẹli.
7 Hĩndĩ o yothe ingĩkaanĩrĩra, njuge rũrĩrĩ kana ũthamaki mũna ũmunyũrwo na mĩri, na unangwo, o na ũniinwo,
Bí ó bá jẹ́ ìgbà kan, tí èmi kéde kí orílẹ̀-èdè tàbí ìjọba kan di fífà tu láti dojúdé àti láti parun,
8 naruo rũrĩrĩ rũu ngaanĩtie rũngĩĩrira, rũtigane na ũũru waruo, nĩngaigua tha, njage kũrũĩka ũũru ũcio njiirĩire kũrũĩka.
tí orílẹ̀-èdè ti mo kìlọ̀ fún bá yípadà kúrò nínú ìwà búburú wọn, nígbà náà ni Èmi yóò yí ọkàn mi padà nínú àjálù tí mo ti rò láti ṣe sí wọn.
9 Ningĩ ihinda rĩngĩ ingĩkaanĩrĩra njuge rũrĩrĩ kana ũthamaki mũna wakwo nĩguo wĩhaande,
Ní ìgbà mìíràn tí èmi bá tún kéde láti tẹ̀dó tàbí gbin orílẹ̀-èdè kan tàbí ìjọba kan.
10 naruo rũrĩrĩ rũu rũcooke rwĩke maũndũ marĩa nyonaga marĩ mooru na rwage kũnjathĩkĩra-rĩ, nĩngericũkwo, njage kũrũĩka wega ũcio njugĩte nĩngũrũĩka.
Bí ó bá sì ṣe búburú níwájú mi, tí kò sì gba ohùn mi gbọ́, nígbà náà ni èmi yóò yí ọkàn mi padà ní ti rere, èyí tí mo wí pé, èmi ó ṣe fún wọn.
11 “Nĩ ũndũ ũcio, rĩu ĩra andũ a Juda na arĩa matũũraga Jerusalemu atĩrĩ, ‘Jehova ekuuga atĩrĩ: Ta rorai muone! Nĩndĩrahaarĩria kũmũrehera mwanangĩko na ngathugunda njĩra ya kũmũũkĩrĩra. Nĩ ũndũ ũcio, garũrũkai mũtigane na mĩthiĩre yanyu mĩũru, mũndũ o mũndũ wanyu, na mũgarũrĩre mĩthiĩre yanyu na ciĩko cianyu.’
“Ǹjẹ́ nísinsin yìí, sọ fún àwọn ènìyàn Juda àti àwọn olùgbé Jerusalẹmu wí pé, ‘Báyìí ní Olúwa wí: Wò ó! Èmi ń gbèrò ibi sí yin, èmi sì ń ṣe ìpinnu kan lórí yín. Nítorí náà ẹ yípadà kúrò lọ́nà búburú yín kí olúkúlùkù yín sì tún ọ̀nà àti ìṣe rẹ̀ ṣe.’
12 No-o magaacookia moige atĩrĩ, ‘Hatirĩ bata wa gũtaarwo. Tũgũthiĩ na mbere na mĩbango iitũ; mũndũ o mũndũ witũ ekũrũmĩrĩra ũremi wa ngoro yake thũku.’”
Ṣùgbọ́n wọn yóò sọ wí pé, ‘Kò ṣe nǹkan kan, àwa yóò tẹ̀síwájú nínú èrò wa, ẹnìkọ̀ọ̀kan wa, yóò hùwà agídí ọkàn búburú rẹ̀.’”
13 Nĩ ũndũ ũcio Jehova ekuuga atĩrĩ: “Tuĩriai harĩ ndũrĩrĩ: Nũũ ũrĩ waigua ũndũ ta ũyũ? Ũndũ ũrĩ magigi mũno nĩwĩkĩtwo nĩ Isiraeli, ũrĩa mũirĩtu gathirange!
Nítorí náà báyìí ni Olúwa wí: “Ẹ béèrè nínú orílẹ̀-èdè, ẹni tí ó bá ti gbọ́ irú nǹkan wọ̀nyí ri? Ohun tí ó burú gidi ni wúńdíá Israẹli ti ṣe.
14 Tharunji ya Lebanoni-rĩ, ĩrĩ yaaga hurũrũka-inĩ ciakĩo cia mahiga? Maaĩ mahehu makĩo marĩa moimaga matherũkĩro-inĩ ma kũraya-rĩ, marĩ maga gũtherera?
Ǹjẹ́ omi ojo dídì Lebanoni yóò ha dá láti máa sàn láti ibi àpáta? Tàbí odò tí ó jìnnà, tí ó tútù, tí ó ń sàn, yóò ha gbẹ bí?
15 No rĩrĩ, andũ akwa nĩmariganĩirwo nĩ niĩ; macinagĩra mĩhianano ĩtarĩ kĩene ũbumba, ĩrĩa yatũmire mahĩngwo mĩthiĩre-inĩ yao, makĩaga kũrũmĩrĩra mĩthiĩre ĩrĩa ya tene. Yatũmire magerere tũcĩra twa mĩkĩra, o na barabara iria itarĩ thondeke.
Nítorí àwọn ènìyàn mi gbàgbé mi, wọ́n sun tùràrí fún òrìṣà asán, tí ó mú wọn kọsẹ̀ ní ọ̀nà wọn, àti ọ̀nà wọn àtijọ́. Wọ́n mú wọn rìn ní ọ̀nà àtijọ́, àti ní ojú ọ̀nà ti a kò ṣe.
16 Bũrũri wao ũgaatigwo ũrĩ mwanangĩku, ũgaatuĩka kũndũ gwa kũnyararwo nginya tene; arĩa othe makaahĩtũkĩra kuo-rĩ, nĩmakagega makĩinagia mĩtwe.
Ilẹ̀ wọn yóò wà lásán yóò sì di nǹkan ẹ̀gàn títí láé, gbogbo àwọn tí ó ń kọjá yóò bẹ̀rù, wọn yóò sì mi orí wọn.
17 O ta rũhuho rũkĩhurutana kuuma mwena wa irathĩro, noguo ngaamahurunja mbere ya thũ ciao; ngaamahutatĩra na njage kũmoonia ũthiũ wakwa mũthenya ũrĩa magaakorwo nĩ mwanangĩko.”
Gẹ́gẹ́ bí afẹ́fẹ́ láti ìlà-oòrùn, Èmi yóò tú wọn ká lójú àwọn ọ̀tá wọn. Èmi yóò sì kọ ẹ̀yìn sí wọn, n kì yóò kọjú sí wọn ní ọjọ́ àjálù wọn.”
18 Nao makiuga atĩrĩ, “Ũkai tũciirĩre ũrĩa tũgũũkĩrĩra Jeremia; nĩ ũndũ ũrutani wa watho ũrĩa athĩnjĩri-Ngai marutanaga ndũkoora, kana kĩrĩra kĩa andũ arĩa oogĩ kĩũre, o na kana ndũmĩrĩri ya anabii yũre. Nĩ ũndũ ũcio ũkai, tũmũtharĩkĩre na nĩmĩ ciitũ, na tũtikarũmbũiye ũndũ o wothe ekuuga.”
Wọ́n sọ wí pé, “Wá, jẹ́ kí a lọ ṣọ̀tẹ̀ sí Jeremiah, nítorí òfin ìkọ́ni láti ẹnu àwọn àlùfáà kì yóò jásí asán, tàbí ìmọ̀ràn fún àwọn ọlọ́gbọ́n tàbí ọ̀rọ̀ láti ẹnu àwọn wòlíì. Nítorí náà wá, ẹ jẹ́ kí a kọlù ú pẹ̀lú ahọ́n wa, kí a má sì ṣe tẹ́tí sí ohunkóhun tí ó bá sọ.”
19 Ta thikĩrĩria, Wee Jehova; igua ũrĩa aya aathitangi maroiga!
Dẹtí sí ọ̀rọ̀ mi Olúwa, gbọ́ ohun tí àwọn tí ó fi mí sùn ń sọ.
20 Wega-rĩ, no ũrĩhwo na ũũru? No rĩrĩ, andũ acio nĩmanyenjeire irima. Ta ririkana ũrĩa ndaarũgamire mbere yaku, na ngĩmarĩrĩria, nĩguo ngirĩrĩrie marakara maku matikamakore.
Ṣe kí a fi rere san búburú? Síbẹ̀ wọ́n ti gbẹ́ kòtò fún mi. Rántí pé mo dúró níwájú rẹ, mo sì sọ̀rọ̀ nítorí wọn, láti yí ìbínú rẹ kúrò lọ́dọ̀ wọn.
21 Nĩ ũndũ ũcio rekereria ciana ciao ngʼaragu; cineane, iniinwo na rũhiũ rwa njora. Reke atumia ao matigwo matarĩ ciana, na marĩ a ndigwa; rekereria arũme ao mooragwo, o nao aanake ao mooragĩrwo mbaara-inĩ na rũhiũ rwa njora.
Nítorí náà, jẹ́ kí ìyàn mú ọmọ wọn jọ̀wọ́ wọn fún ọwọ́ idà jẹ́ kí ìyàwó wọn kí ó di aláìlọ́mọ àti opó jẹ́ kí a pa àwọn ọkùnrin wọn kí a sì fi idà pa àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin wọn lójú ogun.
22 Kĩrĩro kĩroiguuo kuuma nyũmba-inĩ ciao rĩrĩa ũkaarehe andũ a kũmatharĩkĩra hi na hi, nĩ ũndũ nĩmanyenjeire irima nĩguo maanyite, na makanyumbĩkĩra mĩtego ya kũnyiita magũrũ makwa.
Jẹ́ kí a gbọ́ ohùn ẹkún láti ilé wọn nígbà tí ó bá mu àwọn jagunjagun kọlù wọ́n lójijì nítorí wọ́n ti gbẹ́ kòtò láti mú mi. Wọ́n ti dẹ okùn fún ẹsẹ̀ mi.
23 No wee nĩũũĩ, Wee Jehova, ũrĩa wothe manjiirĩire nĩguo manjũrage. Tiga kũmarekera mahĩtia mao, kana kũhuura mehia macio mao mehere ũthiũ-inĩ waku. No marongʼaũranĩrio thĩ mbere yaku; meeke maũndũ macio rĩrĩa ũgaakorwo ũrakarĩte.
Ṣùgbọ́n ìwọ Olúwa mọ gbogbo ète wọn láti pa mí, má ṣe dárí ẹ̀bi wọn jì wọ́n bẹ́ẹ̀ ni má ṣe pa ẹ̀ṣẹ̀ wọn rẹ́ kúrò lójú rẹ. Jẹ́ kí wọn kí ó ṣubú níwájú rẹ, bẹ́ẹ̀ ni kí ìwọ kí ó sì ṣe sí wọn nígbà ìbínú rẹ.

< Jeremia 18 >