< Isaia 52 >
1 Arahũka, arahũka, wee Zayuni, wĩĩkĩre hinya. Ĩkĩra nguo ciaku iria irĩ riiri, o wee Jerusalemu, itũũra rĩrĩa inene na rĩamũre. Nĩgũkorwo kuuma rĩu thĩinĩ waku gũtigacooka gũtoonya mũndũ ũtarĩ mũruu kana mũndũ ũrĩ na thaahu.
Jí, jí, ìwọ Sioni, wọ ara rẹ ní agbára. Gbé aṣọ ògo rẹ wọ̀, ìwọ Jerusalẹmu, ìlú mímọ́ n nì. Àwọn aláìkọlà àti aláìmọ́ kì yóò wọ inú rẹ mọ́.
2 Wĩribaribe rũkũngũ; ũkĩra, ũikarĩre gĩtĩ kĩa ũnene, wee Jerusalemu. Wĩohore mĩnyororo ĩyo ĩrĩ ngingo yaku, wee mwarĩ wa Zayuni, o wee ũtũire ũrĩ muohe.
Gbọn eruku rẹ kúrò; dìde sókè, kí o sì gúnwà, ìwọ Jerusalẹmu. Bọ́ ẹ̀wọ̀n tí ń bẹ lọ́rùn rẹ kúrò, ìwọ ọ̀dọ́mọbìnrin ìgbèkùn Sioni.
3 Nĩgũkorwo Jehova ekuuga atĩrĩ: “Wee wendirio ũtarutĩirwo kĩndũ, na ũgaakũũrwo ũtarutĩirwo mbeeca.”
Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa wí, “Ọ̀fẹ́ ni a tà ọ́, láìsanwó ni a ó sì rà ọ́ padà.”
4 Nĩgũkorwo Mwathani Jehova ekuuga atĩrĩ: “Tene andũ akwa maikũrũkire bũrũri wa Misiri magĩthiĩ gũtũũra marĩ ageni kuo; thuutha ũyũ andũ a Ashuri nĩmamahinyĩrĩirie.”
Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí. “Ní ìgbà àkọ́kọ́ àwọn ènìyàn mi sọ̀kalẹ̀ lọ sí Ejibiti láti gbé; láìpẹ́ ni Asiria pọ́n wọn lójú.
5 Jehova ekũũria atĩrĩ, “Rĩu-rĩ, nĩ kĩĩ ndĩ nakĩo? “Nĩgũkorwo andũ akwa maatahirwo o ũguo tũhũ, nao andũ arĩa mamaathaga no kũmanyũrũria. Narĩo rĩĩtwa rĩakwa rĩcambagio hĩndĩ ciothe,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
“Àti ní àkókò yìí, kí ni mo ní níbí?” ni Olúwa wí. “Nítorí a ti kó àwọn ènìyàn mi lọ lọ́fẹ̀ẹ́, àwọn tí ó sì ń jẹ ọba lórí wọn fi wọ́n ṣẹlẹ́yà,” ni Olúwa wí. “Àti ní ọjọọjọ́ orúkọ mi ni asọ̀rọ̀-òdì sí nígbà gbogbo.
6 “Nĩ ũndũ ũcio andũ akwa nĩmakamenya rĩĩtwa rĩakwa; mũthenya ũcio nĩmakamenya atĩ nĩ niĩ ndaaririe ũhoro ũcio o tene. Ĩĩ nĩguo, nĩ niĩ ndawaririe.”
Nítorí náà àwọn ènìyàn mi yóò mọ orúkọ mi; nítorí ní ọjọ́ náà, wọn yóò mọ̀ pé, Èmi ni ó ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ rẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni, Èmi ni.”
7 Kaĩ magũrũ ma mũndũ ũrĩa ũrarehe ũhoro mwega, nĩmagĩrĩire kũu irĩma-inĩ igũrũ-ĩ, o ũcio ũrahunjanĩria ũhoro wa thayũ, na akarehe ũhoro mwega wa maũndũ magĩrĩru, o na akahunjanĩria ũhoro wa kũhonokania, o we ũrĩa ũreera Zayuni atĩrĩ, “Ngai waku nĩwe ũrathamaka!”
Báwo ni ó ṣe dára tó lórí òkè ẹsẹ̀ àwọn tí ó mú ìyìnrere ayọ̀ wá, tí wọ́n kéde àlàáfíà, tí ó mú ìyìnrere wá, tí ó kéde ìgbàlà, tí ó sọ fún Sioni pé, “Ọlọ́run rẹ ń jẹ ọba!”
8 Atĩrĩrĩ, ta thikĩrĩria! Arangĩri aku nĩmaranĩrĩra; maranĩrĩra nĩ gũkena marĩ hamwe. Rĩrĩa Jehova agaacooka Zayuni, nĩmakeyonera na maitho mao.
Tẹ́tí sílẹ̀! Àwọn olùṣọ́ rẹ gbé ohùn wọn sókè wọ́n kígbe papọ̀ fún ayọ̀. Nígbà tí Olúwa padà sí Sioni, wọn yóò rí i pẹ̀lú ojú u wọn.
9 Atĩrĩrĩ, inyuĩ kũndũ kũrĩa kwanangĩtwo kwa Jerusalemu, ambĩrĩriai kũina nyĩmbo cia gĩkeno, nĩgũkorwo Jehova nĩahooreretie andũ ake, na agakũũra Jerusalemu.
Ẹ bú sí orin ayọ̀ papọ̀, ẹ̀yin ahoro Jerusalẹmu, nítorí Olúwa ti tu àwọn ènìyàn rẹ̀ nínú, ó sì ti ra Jerusalẹmu padà.
10 Jehova nĩakaguũria guoko gwake gũtheru harĩ ndũrĩrĩ ciothe, ikuone na maitho mao, nacio ituri ciothe cia thĩ nĩcikoona ũhonokanio wa Ngai witũ.
Olúwa yóò ṣí apá mímọ́ rẹ̀ sílẹ̀ ní ojú gbogbo orílẹ̀-èdè, àti gbogbo òpin ilẹ̀ ayé yóò rí ìgbàlà Ọlọ́run wa.
11 Eherai, eherai, umai kũu! Mũtikahutie kĩndũ kĩrĩ thaahu! Umai kũu na mwĩtherie, inyuĩ mũkuuaga indo cia Jehova.
Ẹ túká, ẹ túká, ẹ jáde kúrò níhìn-ín yìí! Ẹ má fọwọ́ kan ohun àìmọ́ kan! Ẹ jáde kúrò nínú rẹ̀ kí ẹ sì di mímọ́, ẹ̀yin tí ẹ̀ ń gbé ohun èlò Olúwa.
12 No rĩrĩ, mũtikoima na ihenya, kana mũthiĩ mũhanyũkĩte; nĩgũkorwo Jehova nĩwe ũkaamũtongoria, Ngai wa Isiraeli nĩwe ũkaamuuma thuutha, amũgitĩre.
Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kì yóò yára kúrò tàbí kí ẹ sáré lọ; nítorí Olúwa ni yóò síwájú yín lọ, Ọlọ́run Israẹli ni yóò sì ṣe ààbò lẹ́yìn ín yín.
13 Atĩrĩrĩ, ndungata yakwa ĩgeekaga maũndũ na ũũgĩ; nĩĩkambarario na yambatĩrio, o na ĩtũũgĩrio mũno.
Kíyèsi i, ìránṣẹ́ mi yóò hùwà ọlọ́gbọ́n; òun ni a ó gbé sókè tí a ó sì gbéga a ó sì gbé e lékè gidigidi.
14 O ta ũrĩa andũ aingĩ maagegirio mũno nĩ ũndũ wake, tondũ gĩthiithi gĩake nĩgĩathũkĩtio mũno, gĩgakĩra kĩa mũndũ o wothe, na mũhianĩre wake ũgathũkio gũkĩra mũhianĩre wa andũ,
Gẹ́gẹ́ bí a ti rí ọ̀pọ̀lọpọ̀ tí wọ́n ń bu ọlá fún un— ìwò ojú rẹ ni a ti bàjẹ́ kọjá ti ẹnikẹ́ni àti ìrísí rẹ̀ ní a ti bàjẹ́ kọjá ohun tí ènìyàn ń fẹ́.
15 ũguo noguo akaamakia ndũrĩrĩ nyingĩ, nao athamaki nĩmagatumia tũnua twao nĩ ũndũ wake. Nĩgũkorwo maũndũ marĩa materĩtwo, nĩmakamoona, na maũndũ marĩa mataiguĩte, nĩmakamenya ũhoro wamo.
Bẹ́ẹ̀ ni yóò ṣe bomirin àwọn orílẹ̀-èdè ká, àwọn ọba yóò sì pa ẹnu wọn mọ́ nítorí rẹ̀. Nítorí ohun tí a kò sọ fún wọn, wọn yóò rí i, àti ohun tí wọn kò tí ì gbọ́, ni yóò sì yé wọn.