< Isaia 51 >
1 “Atĩrĩrĩ, inyuĩ mũrũmagĩrĩra maũndũ ma ũthingu ta thikĩrĩriai, o inyuĩ mũrongoragia Jehova: Rorai rwaro rwa ihiga rũrĩa mwarutirwo, o na kĩenjero kĩa mahiga kĩrĩa mwenjirwo;
“Tẹ́tí sí mi, ẹ̀yin tí ó ń lépa òdodo àti ẹ̀yin tí ń wá Olúwa. Wo àpáta, nínú èyí tí a ti gé yín jáde àti ihò òkúta níbi tí a ti gbẹ́ yín jáde;
2 ta rorai Iburahĩmu, o we ithe wanyu, o na Sara, ũrĩa wamũciarire. Nĩgũkorwo hĩndĩ ĩrĩa aarĩ o wiki nĩguo ndamwĩtire, na ngĩmũrathima, ngĩtũma aingĩhe.
ẹ wo Abrahamu baba yín, àti Sara, ẹni tó bí i yín. Nígbà tí mo pè é, òun nìkan ni, Èmi sì bùkún un, mo sì ṣọ́ ọ di ọ̀pọ̀lọpọ̀.
3 Ti-itherũ Jehova nĩakahooreria Zayuni, o na ahoorerie kũndũ gwakuo kũrĩa kwanangĩtwo; werũ wakuo akaaũtua o ta Edeni, na rũngʼũrĩ rwakuo arũtue o ta mũgũnda wa Jehova. Kũu guothe gũkaiyũra gĩkeno, na gũcanjamũka ngoro, na gũcookagia ngaatho, o gũkĩinagwo nyĩmbo.
Dájúdájú, Olúwa yóò tu Sioni nínú yóò sì bojú àánú wo gbogbo ahoro rẹ̀; Òun yóò sọ gbogbo aṣálẹ̀ rẹ̀ di Edeni, àti aṣálẹ̀ rẹ̀ yóò rí bí ọgbà Olúwa. Ayọ̀ àti inú dídùn ni a ó rí nínú rẹ̀, ọpẹ́ àti ariwo orín kíkọ.
4 “Inyuĩ andũ akwa ta thikĩrĩriai, na inyuĩ rũrĩrĩ rwakwa, njiguai: Nĩgũkorwo watho ũkoima harĩ niĩ; nakĩo kĩhooto gĩakwa nĩkĩo gĩgaatuĩka ũtheri wa ndũrĩrĩ.
“Tẹ́tí sí mi, ẹ̀yin ènìyàn mi; gbọ́ tèmi, ẹ̀yin orílẹ̀-èdè mi. Òfin yóò ti ọ̀dọ̀ mi jáde wá; ìdájọ́ mi yóò di ìmọ́lẹ̀ sí àwọn orílẹ̀-èdè.
5 Ũhoro wakwa wa ũthingu nĩũrooka o na ihenya, nakuo kũhonokania gwakwa kũrĩ hakuhĩ kuoneka, o nakuo guoko gwakwa nĩkuo gũgaatuĩra andũ a ndũrĩrĩ ciira wa kĩhooto. Andũ a icigĩrĩra-inĩ nĩ niĩ magaacũthĩrĩria na meterere guoko gwakwa marĩ na mwĩhoko.
Òdodo mi ń bọ̀ wá kíkankíkan, ìgbàlà mi ń bọ̀ lójú ọ̀nà, àti apá mi yóò sì mú ìdájọ́ wá sí àwọn orílẹ̀-èdè. Àwọn erékùṣù yóò wò mí wọn yóò sì dúró ní ìrètí fún apá mi.
6 Tiirai maitho manyu na igũrũ, na mũrore thĩ ĩrĩa ĩrĩ mũhuro; igũrũ rĩkaabuĩria o ta ndogo, nayo thĩ ĩthire o ta ũrĩa nguo ĩthiraga, nao atũũri ao makuage o ũguo ta ngi. No rĩrĩ, ũhonokio wakwa nĩwagũtũũra nginya tene, naguo ũthingu wakwa ndũrĩ hĩndĩ ũgaathira.
Gbé ojú rẹ sókè sí àwọn ọ̀run, wo ilẹ̀ ní ìsàlẹ̀ ilẹ̀; àwọn ọ̀run yóò pòórá bí èéfín, ilẹ̀ yóò sì gbó bí ẹ̀wù àwọn olùgbé inú rẹ̀ yóò kú gẹ́gẹ́ bí àwọn eṣinṣin. Ṣùgbọ́n ìgbàlà mi yóò wà títí láé, òdodo mi kì yóò yẹ̀ láé.
7 “Ta njiguai, inyuĩ andũ arĩa mũũĩ ũhoro wa ũthingu, o inyuĩ andũ arĩa mũrũmĩtie watho wakwa ngoro-inĩ cianyu: Mũtigetigĩre kũmenwo nĩ andũ, o na kana mũmakio nĩ irumi iria mamũrumaga nacio.
“Ẹ gbọ́ mi, ẹ̀yin tí ó mọ ohun òtítọ́, ẹ̀yin ènìyàn tí ó ní òfin mi ní àyà yín. Ẹ má ṣe bẹ̀rù ẹ̀gàn àwọn ènìyàn tàbí kí ẹ̀rù èébú wọn já a yín láyà.
8 Nĩgũkorwo makaarĩĩo nĩ memenyi mathire biũ o ta nguo; na marĩĩo nĩ igunyũ o ta marĩ guoya wa ngʼondu. No rĩrĩ, ũhoro wakwa wa ũthingu nĩ wa gũtũũra nginya tene, naguo ũhonokio wakwa ũtũũre nginya njiarwa-inĩ ciothe.”
Nítorí kòkòrò yóò mú wọn lá bí aṣọ, ìdin yóò sì mú wọn jẹ bí ẹ̀gbọ̀n òwú. Ṣùgbọ́n òdodo mi yóò wà títí ayérayé, àti ìgbàlà mi láti ìrandíran.”
9 Arahũka, arahũka! Wĩĩkĩre hinya, wee guoko kwa Jehova; arahũka o ta ũrĩa waarahũkire matukũ marĩa ma tene, warahũke o ta hĩndĩ ya njiarwa cia tene. Githĩ wee tiwe watinangirie Rahabu tũcunjĩ, o wee watheecangire nyamũ ĩyo nene, ũkĩmĩtũrĩkania?
Dìde, dìde! Kí o sì wọ ara rẹ ní agbára ìwọ apá Olúwa; dìde gẹ́gẹ́ bí i ti ọjọ́ ìgbà n nì, àti gẹ́gẹ́ bí i ti ìran àtijọ́. Ìwọ kọ́ lo ké Rahabu sí wẹ́wẹ́ tí o sì fa ẹ̀mí búburú ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ?
10 Githĩ tiwe wahũithirie iria, maaĩ ma kũndũ kũrĩa kũriku mũno, o wee watemire njĩra kũu iria-inĩ kũrĩa kũriku, nĩgeetha andũ arĩa wakũũrĩte maringĩre yo?
Ìwọ kọ́ ni ó gbẹ omi Òkun bí àti àwọn omi inú ọ̀gbun, tí o sì ṣe ọ̀nà nínú ìsàlẹ̀ Òkun tó bẹ́ẹ̀ tí àwọn ẹni ìràpadà yóò fi le là á kọjá?
11 Andũ arĩa akũũre a Jehova nĩmagacooka. Nao magaatoonya Zayuni makĩinaga; nĩmagekĩrwo thũmbĩ ya gĩkeno gĩa tene na tene. Magaakena na macanjamũke, nakĩo kĩeha na mũcaayo nĩigathira biũ.
Àwọn ẹni ìràpadà Olúwa yóò padà wá. Wọn yóò wọ Sioni wá pẹ̀lú orin kíkọ; ayọ̀ ayérayé ni yóò sì bo orí wọn. Ayọ̀ àti inú dídùn yóò sì bà lé wọn ìbànújẹ́ àti ìtìjú yóò sì sá kúrò.
12 “Niĩ, o niĩ mwene-rĩ, nĩ niĩ ndĩmũhooreragia. Wee ũrĩ ũ, atĩ nĩguo wĩtigĩre andũ arĩa makuuaga, na ũgetigĩra ariũ a andũ arĩa magaatuuo o ta nyeki,
“Èmi, àní Èmi, èmi ni ẹni tí ó tù ọ́ nínú. Ta ni ọ́ tí o fi ń bẹ̀rù ènìyàn ẹlẹ́ran ara, àti ọmọ ènìyàn, tí ó jẹ́ koríko lásán,
13 nawe ũkariganĩrwo nĩ Jehova ũrĩa wakũũmbire, o we ũrĩa watambũrũkirie matu, na agĩaka mĩthingi ya thĩ, atĩ nĩguo o ũtũũrage na guoya o mũthenya nĩ ũndũ wa mangʼũrĩ ma mũhinyanĩrĩria rĩrĩa ekwĩhaarĩria aniinane? Namo mangʼũrĩ ma mũhinyanĩrĩria ũcio-rĩ, makĩrĩ ha?
tí ìwọ sì gbàgbé Olúwa ẹlẹ́dàá rẹ, ẹni tí ó ta àwọn ọ̀run tí ó sì fi ìpìlẹ̀ ayé sọlẹ̀, tí ẹ sì ń gbé nínú ìpayà lójoojúmọ́ nítorí ìbínú àwọn aninilára, tí wọ́n sì gbẹ́kẹ̀lé ìpanirun? Nítorí ibo ni ìbínú àwọn aninilára gbé wà?
14 Nao oohwo arĩa marainaina nĩ guoya nĩmekuohorwo o narua; matigakuĩra kũu marima-inĩ ma njeera, o na kana irio ciao ciage.
Àwọn ẹlẹ́wọ̀n tí ń ṣojo la ó dá sílẹ̀ ní àìpẹ́ jọjọ wọn kò ní kú sínú túbú wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò ní ṣe aláìní àkàrà.
15 Nĩgũkorwo nĩ niĩ Jehova Ngai wanyu, ũrĩa ũtũmaga iria rĩikie ndiihũ nĩguo makũmbĩ marĩo makaruruma; Jehova Mwene-Hinya-Wothe nĩrĩo rĩĩtwa rĩake.
Nítorí Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ, tí ó ń ru Òkun sókè tó bẹ́ẹ̀ tí ìgbì rẹ̀ fi ń pariwo Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀.
16 Nĩnjĩkĩrĩte ciugo ciakwa kanua-inĩ gaku, na ngakũhumbĩra na kĩĩruru gĩa guoko gwakwa, o niĩ ndatambũrũkirie matu harĩa marĩ, na ngĩaka mĩthingi ya thĩ, o niĩ njĩĩraga andũ a Zayuni atĩrĩ, ‘Inyuĩ mũrĩ andũ akwa.’”
Mo ti fi ọ̀rọ̀ mi sí ẹnu rẹ mo sì ti fi òjìji ọwọ́ mi bò ọ́, Èmi tí mo tẹ́ àwọn ọ̀run sí ààyè rẹ̀, ẹni tí ó fi ìpìlẹ̀ ilẹ̀ ayé lélẹ̀, àti ẹni tí ó sọ fún Sioni pé, ‘Ẹ̀yin ni ènìyàn mi.’”
17 Arahũka, arahũka! Wee Jerusalemu ũkĩra, o wee ũnyuĩrĩire gĩkombe kĩa mangʼũrĩ ma Jehova, ũnengereirio kuuma guoko-inĩ gwake, o wee ũnyuĩrĩire kuuma mbakũri ĩrĩa ĩtũmaga andũ matũgũũge na ũkamĩinĩkĩrĩria.
Jí, jí! Gbéra nílẹ̀ ìwọ Jerusalẹmu, ìwọ tí o ti mu láti ọwọ́ Olúwa ago ìbínú rẹ̀, ìwọ tí o ti fà á mu dé gẹ̀dẹ̀gẹ́dẹ̀ tí ó n mú kí ènìyàn ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n.
18 Harĩ ariũ ake othe arĩa aaciarire, gũtirĩ o na ũmwe ũngĩmũtongoria; o na ningĩ ariũ ake othe arĩa aarerire-rĩ, gũtirĩ o na ũmwe ũngĩmũnyiita guoko.
Nínú gbogbo ọmọ tí ó bí kò sí ọ̀kankan tí ó lè tọ́ ọ ṣọ́nà nínú gbogbo ọmọ tí ó tọ́ kò sí èyí tí ó le fà á lọ́wọ́.
19 Mogwati maya meerĩ nĩmo magũkorete; nũũ ũgaagĩkũhooreria? Mogwati macio nĩ mwanangĩko na ũniinani, ningĩ nĩ ngʼaragu o na rũhiũ rwa njora; nũũ ũgaagĩkũhooreria?
Àjálù ìlọ́po ìlọ́po yìí ti dé bá ọ— ta ni yóò tù ọ́ nínú? Ìparun àti ìdahoro, ìyàn àti idà ta ni yó pẹ̀tù sí ọ lọ́kàn?
20 Ariũ aku nĩmaringĩkĩte; nao makomete macemanĩrio-inĩ ma njĩra ciothe, magakoma o ta thiiya ĩnyiitĩtwo nĩ mũtego. Maiyũrĩtwo nĩ mangʼũrĩ ma Jehova, na ikũũma rĩa Ngai wanyu.
Àwọn ọmọkùnrin rẹ ti dákú; wọ́n sùn sí oríta gbogbo òpópónà, gẹ́gẹ́ bí etu tí a dé mọ́nú àwọ̀n. Ìbínú Olúwa ti kún inú wọn fọ́fọ́ àti ìbáwí Ọlọ́run yín.
21 Nĩ ũndũ ũcio igua ũhoro ũyũ, wee ũnyariirĩtwo, ũkarĩĩo, no ti ndibei ĩkũrĩĩte.
Nítorí náà ẹ gbọ́ èyí, ẹ̀yin tí a ti ṣẹ́ níṣẹ̀ẹ́, tí ọtí ń pa, ṣùgbọ́n kì í ṣe fún wáìnì.
22 Mwathani Jehova Ngai waku ũrĩa ũgitagĩra andũ ake, ekuuga ũũ: “Atĩrĩrĩ, nĩngwehereirie gĩkombe kĩrĩa gĩatũmire ũtũgũge, ngakĩruta guoko-inĩ gwaku; o na ngakwehereria mbakũri ya mangʼũrĩ makwa, na ndũgacooka kũmĩnyuĩra rĩngĩ.
Ohun tí Olúwa Olódùmarè yín wí nìyìí, Ọlọ́run rẹ, ẹni tí ó ń pa ènìyàn rẹ̀ mọ́, “Kíyèsi i, mo ti mú un kúrò ní ọwọ́ rẹ ago tí ó mú ọ ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n; láti inú ago náà, ẹ̀kún ìbínú mi, ni ìwọ kì yóò mu mọ́.
23 Nĩnganeana mbakũri ĩyo moko-inĩ ma arĩa makũnyariiraga, o arĩa maakwĩrire atĩrĩ, ‘Wĩgũithie thĩ, nĩguo tũkũgerere igũrũ.’ Nawe ũgĩkoma, mũgongo waku ũgĩtuĩka taarĩ thĩ, na ũkĩũtua taarĩ njĩra nĩguo andũ acio makũgeragĩre igũrũ.”
Èmi yóò fi lé àwọn apọ́nilójú rẹ lọ́wọ́, àwọn tí ó wí fún ọ pé, ‘Dọ̀bálẹ̀, tó bẹ́ẹ̀ tí a ó fi máa rìn lórí rẹ.’ Ìwọ náà ṣe ẹ̀yìn rẹ gẹ́gẹ́ bí ilẹ̀ gẹ́gẹ́ bí òpópónà láti máa rìn lórí i rẹ̀.”