< Isaia 3 >

1 Atĩrĩrĩ, Mwathani, Jehova Mwene-Hinya-Wothe, arĩ hakuhĩ kwehereria Jerusalemu na Juda ũteithio wao na kĩrĩa kĩmatiiragĩrĩra, amehererie ũteithio wothe wa irio na wa maaĩ,
Kíyèsi i, Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, fẹ́ mú ìpèsè àti ìrànlọ́wọ́ kúrò ní Jerusalẹmu àti Juda gbogbo ìpèsè oúnjẹ àti ìpèsè omi.
2 o na amehererie mũndũ ũrĩa njamba na mũrũi wa mbaara, na mũtuanĩri ciira na mũnabii, na mũragũri na mũthuuri wa kĩama,
Àwọn akíkanjú àti jagunjagun, adájọ́ àti wòlíì, aláfọ̀ṣẹ àti alàgbà,
3 na mũtongoria wa gĩkundi gĩa thigari mĩrongo ĩtano, na mũheani kĩrĩra, na mũbundi mũũgĩ, o na mũndũ-mũgo mũũgĩ.
balógun àádọ́ta àti àwọn ènìyàn, onípò gíga; olùdámọ̀ràn, oníṣọ̀nà tí ó dáńtọ́ àti ògbójú oníṣègùn.
4 Tũhĩĩ nĩtuo ngaatua anene ao; na maathagwo nĩ tũkenge.
“Èmi ó sọ àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin di aláṣẹ wọn, ọ̀dọ́mọdé lásán làsàn ni yóò sì máa jẹ ọba lórí i wọn.”
5 Andũ nĩmakahiinyanĩrĩria: o mũndũ akaahinyĩrĩria ũrĩa ũngĩ, mũndũ wa itũũra okĩrĩre mũndũ wa itũũra rĩake. Arĩa anini nĩmagookĩrĩra arĩa akũrũ, nao arĩa matarĩ ngumo mokĩrĩre mũndũ ũrĩa mũtĩĩku.
Àwọn ènìyàn yóò sì máa pọ́n ọmọnìkejì, wọn lójú ẹnìkan sí ẹnìkejì rẹ̀, aládùúgbò sí aládùúgbò rẹ̀. Àwọn ọ̀dọ́ yóò gbógun ti àwọn àgbàgbà, àwọn mẹ̀kúnnù yóò dìde sí ọlọ́lá.
6 Mũndũ nĩakanyiita ũmwe wa ariũ a nyina arĩ gwa ithe mũciĩ, amwĩre atĩrĩ, “Wee ũrĩ na nguo ya igũrũ, tuĩka mũtongoria witũ; ũreke kũndũ gũkũ kwanangĩtwo kũgĩe wathani-inĩ waku!”
Ọkùnrin kan yóò di ọ̀kan nínú àwọn arákùnrin rẹ̀ mú, nínú ilé baba rẹ̀, yóò sì wí pé, “Ìwọ́ ní aṣọ, ìwọ máa ṣe olórí wa, sì mójútó àwọn ahoro wọ̀nyí!”
7 Nowe nĩakaanĩrĩra mũthenya ũcio oige atĩrĩ, “Niĩ ndirĩ na kĩhonia. Nĩgũkorwo gwakwa mũciĩ gũtirĩ irio kana nguo, tigai kũndua mũtongoria wa andũ.”
Ṣùgbọ́n ní ọjọ́ náà ni yóò figbe bọnu pé, “Èmi kò ní àtúnṣe kan. Èmi kò ní oúnjẹ, bẹ́ẹ̀ ni n ó ní aṣọ nílé, ẹ má fi mí ṣe olórí àwọn ènìyàn náà.”
8 Nĩgũkorwo Jerusalemu nĩkũratũgũũga, nakuo Juda nĩkũragũa; ciugo na ciĩko ciakuo nĩirokĩrĩra Jehova na makangʼathĩria thiithi wake ũrĩ riiri.
Jerusalẹmu ń ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n Juda ń ṣubú lọ, ọ̀rọ̀ àti ìṣe wọn lòdì sí Olúwa, láti mú ojú ògo rẹ̀ bínú.
9 Ithiithi ciao nĩcio ciumbũraga ũrĩa mahaana; maanĩkaga mehia mao o ta ma Sodomu; o na matimahithaga. Kaĩ marĩ na haaro-ĩ! Nĩo mereheire mwanangĩko.
Ìwò ojú wọn ń jẹ́rìí lòdì sí wọn, wọ́n ń polongo ẹ̀ṣẹ̀ wọn bí i Sodomu; wọn ò fi pamọ́! Ègbé ni fún wọn! Wọ́n ti mú ìparun wá sórí ara wọn.
10 Ha ũhoro wa andũ arĩa athingu, meerei atĩ nĩmakagaacĩra; nĩgũkorwo nĩmakaarĩĩaga maciaro ma maũndũ marĩa maaneka.
Ẹ sọ fún olódodo pé yóò dára fún wọn, nítorí ní àjẹgbádùn ni wọn yóò jẹ èso iṣẹ́ ẹ wọn.
11 No andũ arĩa aaganu, meerei atĩrĩ: kaĩ marĩ na haro-ĩ! Nĩgũkorwo mwanangĩko ũrĩ igũrũ rĩao! Nao makaarĩhwo kũringana na wĩra wa moko mao.
Ègbé ni fún ènìyàn búburú! Ìparun wà lórí i wọn, a ó sì san èrè iṣẹ́ tí ọwọ́ wọn ti ṣe fún wọn.
12 Andũ akwa mahinyagĩrĩrio nĩ ciana, nao andũ-a-nja nĩo mamaathaga. Atĩrĩrĩ inyuĩ andũ akwa, atongoria anyu nĩo mamũhĩtithagia, magatũma muume njĩra ĩrĩa yagĩrĩire.
Àwọn ọ̀dọ́mọdé ni o ń pọ́n àwọn ènìyàn mi lójú àwọn obìnrin ń jẹ ọba lé wọn lórí. Háà! Ènìyàn mi àwọn afinimọ̀nà yín ti ṣì yín lọ́nà, wọn sì mú yín kúrò ní ipa ọ̀nà yín.
13 Jehova nĩaikarĩire gĩtĩ gĩake iciirĩro-inĩ; akarũgama nĩguo aciirithie andũ.
Olúwa bọ sí ipò rẹ̀ ní ìtẹ́ ìdájọ́ Ó dìde láti dá àwọn ènìyàn lẹ́jọ́.
14 Jehova nĩarĩkĩtie gũtuĩra athuuri na atongoria a andũ ake ciira, akameera atĩrĩ: “Nĩ inyuĩ mwanangĩte mũgũnda wakwa wa mĩthabibũ; o na indo iria mũtunyĩte athĩĩni irĩ thĩinĩ wa nyũmba cianyu.”
Olúwa dojú ẹjọ́ kọ àwọn àgbàgbà àti àwọn olórí àwọn ènìyàn rẹ̀. “Ẹ̀yin ni ẹ ti run ọgbà àjàrà mi, ogún àwọn tálákà ń bẹ̀ nínú ilé yín.
15 “Mũhehenjaga andũ akwa, na mũkamemenda mothiũ ma athĩĩni nĩkĩ?” nĩguo Mwathani Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekũũria.
Kín ni èrò yín láti máa run àwọn ènìyàn mi túútúú tí ẹ sì fojú àwọn tálákà ni gbolẹ̀?” ni Olúwa wí, Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
16 Jehova ekuuga atĩrĩ, “Andũ-a-nja a Zayuni nĩetĩĩi, mathiiaga maguucĩtie ngingo, makiuhanaga na maitho mao, na makinyaga na njacĩ magĩthiĩ, na makagambia njingiri iria irĩ thũngʼwa-inĩ ciao.
Olúwa wí pé, “Àwọn obìnrin Sioni jẹ́ agbéraga, wọn ń rìn lọ pẹ̀lú ọrùn tí ó nà tàntàn, tí wọn ń fojú pe ọkùnrin, tí wọn ń sọ̀dí bí wọ́n ti ń yan lọ pẹ̀lú ohun ọ̀ṣọ́ tí ń mì wọnjanwọnjan lọ́rùn ẹsẹ̀ wọn.
17 Nĩ ũndũ ũcio Mwathani nĩagatũma andũ-a-nja acio a Zayuni magĩe na ironda mĩtwe; Jehova nĩakoonania njaga yao.”
Nítorí náà Olúwa yóò mú egbò wá sórí àwọn obìnrin Sioni, Olúwa yóò sì pá wọn ní agbárí.”
18 Mũthenya ũcio Jehova nĩakamaaũra mathaga mao: nĩmo bangiri, na rũtamĩ rwa kuoha njuĩrĩ, na mĩgathĩ ĩrĩa ĩĩhacĩte ta mweri,
Ní ọjọ́ náà, Olúwa yóò já ọ̀ṣọ́ wọn gbà kúrò ti ọwọ́ àti gèlè àti ẹ̀gbà ọrùn tí ó dàbí òṣùpá
19 na icũhĩ cia matũ, na mĩrĩnga ya moko, na taama wa kwĩhumbĩra ũthiũ,
gbogbo yẹtí, ẹ̀gbà ọwọ́ àti ìbòjú,
20 na itambaya cia mũtwe, na irengeeri cia magũrũ, na mĩcibi, na cuba cia maguta manungi wega, na ithiitũ
gbogbo gèlè, ẹ̀gbà ọrùn, ẹsẹ̀ àti àyà, àwọn ìgò tùràrí àti òògùn,
21 na icũhĩ cia mũhũũri cia moko, na icũhĩ cia maniũrũ,
òrùka ọwọ́ àti ti imú,
22 na nguo ndaihu iria njega, na ngũbia, na tũbuti, na nguo cia igũrũ, na tũmondo,
àwọn àtàtà aṣọ, àwọ̀lékè, agbádá àti àpamọ́wọ́,
23 na icicio cia kwĩrora, na nguo cia gatani ĩrĩa njega, na itambaya, na macuka ma ciande.
dígí wọn, aṣọ funfun nigínnigín ìbòrí àti ìbòjú.
24 Handũ ha mũtararĩko mwega gũkaagĩa na mũnungo mũũru; handũ ha mũcibi hagaakorwo mũkanda; handũ ha njuĩrĩ thondeke wega hagĩe kĩhara; handũ ha nguo njega hakaagĩa nguo ya ikũnia; naho handũ ha ũthaka wa mwĩrĩ hagĩe gũcinanwo na ruoro.
Dípò òórùn dídùn, òórùn búburú ni yóò wá, okùn ni yóò wà dípò àmùrè, orí pípá ni yóò dípò irun ti a ṣe ní ọ̀ṣọ́ aṣọ ọ̀fọ̀ ni yóò dípò aṣọ ẹ̀yẹ ìjóná dípò ẹwà.
25 Arũme anyu makooragwo na rũhiũ rwa njora, nacio njamba cianyu cia ita ikaaniinĩrwo mbaara-inĩ.
Àwọn ọkùnrin rẹ yóò ti ipa idà ṣubú, àti àwọn jagunjagun rẹ̀ lójú ogun.
26 Ihingo cia Zayuni nĩigacakaya na igirĩke, na itũũra rĩu rĩkire ihooru, na rĩikare rĩmomoretwo, rĩkagũa thĩ.
Àwọn bodè Sioni yóò sọkún kíkorò, wọn ó ṣọ̀fọ̀, nítorí ó dahoro, yóò jókòó ní orí ilẹ̀.

< Isaia 3 >