< Isaia 19 >

1 Ĩno nĩ ndũmĩrĩri nditũ ĩkoniĩ bũrũri wa Misiri: Atĩrĩrĩ, Jehova ahaicĩte itu rĩhanyũkĩte mũno athiĩte bũrũri wa Misiri. Mĩhianano ya bũrũri wa Misiri irainaina mbere yake, nacio ngoro cia andũ a bũrũri wa Misiri ikaringĩka thĩinĩ wao.
Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Ejibiti. Kíyèsi i, Olúwa gun àwọsánmọ̀ tí ó yára lẹ́ṣin ó sì ń bọ̀ wá sí Ejibiti. Àwọn ère òrìṣà Ejibiti wárìrì níwájú rẹ̀, ọkàn àwọn ará Ejibiti sì ti domi nínú wọn.
2 “Nĩngarahũra Mũmisiri ookĩrĩre Mũmisiri ũrĩa ũngĩ: mũndũ nĩakarũa na mũrũ wa ithe, nake mũndũ wa itũũra ookĩrĩre mũndũ wa itũũra rĩake, narĩo itũũra inene rĩũkĩrĩre itũũra rĩrĩa rĩngĩ, naguo ũthamaki ũũkĩrĩre ũthamaki ũrĩa ũngĩ.
“Èmi yóò rú àwọn ará Ejibiti sókè sí ara wọn arákùnrin yóò bá arákùnrin rẹ̀ jà, aládùúgbò yóò dìde sí aládùúgbò rẹ̀, ìlú yóò dìde sí ìlú, ilẹ̀ ọba sí ilẹ̀ ọba.
3 Andũ a bũrũri wa Misiri nĩmagakua ngoro, nayo mĩbango yao ndĩmĩtue ya tũhũ; makaahooya kĩrĩra kũrĩ ngai cia mĩhianano na kũrĩ maroho ma andũ arĩa makuĩte, o na kũrĩ ago na aragũri.
Àwọn ará Ejibiti yóò sọ ìrètí nù, èmi yóò sì sọ èrò wọn gbogbo di òfo; wọn yóò bá àwọn òrìṣà àti ẹ̀mí àwọn òkú sọ̀rọ̀, àwọn awoṣẹ́ àti àwọn abókùúsọ̀rọ̀.
4 Nĩnganeana andũ a bũrũri wa Misiri wathani-inĩ wa mwathi ũtarĩ tha, na mũthamaki mũũru amathamakĩre,” ũguo nĩguo Mwathani Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga.
Èmi yóò fi Ejibiti lé agbára àwọn ìkà amúnisìn lọ́wọ́, ọba aláìláàánú ni yóò jẹ ọba lé wọn lórí,” ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
5 Maaĩ ma Rũũĩ rwa Nili nĩmakaahũa, na mũkaro waruo ũngʼare na ũũme.
Gbogbo omi inú odò ni yóò gbẹ, gbogbo ilẹ̀ àyíká odò ni yóò gbẹ tí yóò sì sáàpá.
6 Mĩtaro ya maaĩ nĩĩkanunga; tũrũũĩ twa Misiri nĩtũkaahũa tũũme biũ. Namo marura na mathanjĩ nĩmakahooha,
Adágún omi yóò sì di rírùn; àwọn odò ilẹ̀ Ejibiti yóò máa dínkù wọn yóò sì gbẹ. Àwọn koríko odò àti ìrẹ̀tẹ̀ yóò gbẹ,
7 o nayo mĩmera ĩrĩa ĩrĩ hũgũrũrũ-inĩ cia Rũũĩ rwa Nili, gĩtwe-inĩ kĩa rũũĩ rũu, nĩĩkahooha. Indo iria ciothe ĩhaandĩtwo mĩgũnda ĩrĩa ĩrĩ gũkuhĩ na Rũũĩ rwa Nili nĩikooma biũ, na ciũmbũrwo, na itigacooka kuoneka kuo rĩngĩ.
àwọn igi ipadò Naili pẹ̀lú, tí ó wà ní orísun odò, gbogbo oko tí a dá sí ipadò Naili yóò gbẹ dànù tí yóò sì fẹ́ dànù tí kò sì ní sí mọ́.
8 Ategi a thamaki nĩmagacaaya na marĩre, arĩa othe maikagia ndwano ciao Rũũĩ-inĩ rwa Nili; nao arĩa othe maikagia mĩtego yao maaĩ-inĩ macio nĩmakoorwo nĩ hinya.
Àwọn apẹja yóò sọkún kíkorò, àti gbogbo àwọn tí ó ń ju ìwọ̀ sínú odò; odò náà yóò sì máa rùn.
9 Andũ arĩa marutaga wĩra na ndigi cia ũguta ũrĩa mwega nĩmagakua ngoro, na arĩa matumaga mataama marĩa mahoro nĩmakaaga mwĩhoko.
Àwọn tí ó ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú ọ̀gbọ̀ yóò kọminú àwọn ahunṣọ ọ̀gbọ̀ yóò sọ ìrètí nù.
10 Atumi a nguo nĩmagakorwo na kĩeha, na arĩa othe maheagwo mĩcaara nĩmakaigua ũũru ngoro.
Àwọn tí ń ṣiṣẹ́ aṣọ yóò rẹ̀wẹ̀sì, gbogbo àwọn oníṣẹ́ oṣù ni àìsàn ọkàn yóò ṣe.
11 Anene a Zoani nĩmakĩĩgĩte o gũkĩĩga; nao andũ arĩa oogĩ a Firaũni maheanaga kĩrĩra kĩa ũrimũ. Mwakĩhota atĩa kwĩra Firaũni, “Niĩ ndĩ ũmwe wa andũ arĩa oogĩ, ndĩ mũrutwo wa athamaki arĩa a tene?”
Àwọn oníṣẹ́ Ṣoani ti di aláìgbọ́n, àwọn ọlọ́gbọ́n olùdámọ̀ràn Farao ń mú ìmọ̀ràn àìgbọ́n wá. Báwo ló ṣe lè sọ fún Farao pé, “Mo jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn ọlọ́gbọ́n ènìyàn, ọ̀kan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn àwọn ọba àtijọ́.”
12 Andũ aku arĩa oogĩ makĩrĩ ha rĩu? Ta nĩmagĩkuonie na makũmenyithie ũrĩa Jehova Mwene-Hinya-Wothe aciirĩire gwĩka bũrũri wa Misiri.
Níbo ni àwọn ọlọ́gbọ́n ènìyàn rẹ wà báyìí? Jẹ́ kí wọn fihàn ọ́ kí wọn sì sọ ọ́ di mí mọ̀ ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti pinnu lórí Ejibiti.
13 Anene a Zoani makĩĩgĩte o gũkĩĩga, nao atongoria a Nofu makaheeneka; namo mahiga ma koine ma andũ ake nĩmahĩtithĩtie andũ a Misiri.
Àwọn ọmọ-aládé Ṣoani ti di aṣiwèrè, a ti tan àwọn ọmọ-aládé Memfisi jẹ; àwọn òkúta igun ilé tí í ṣe ti ẹ̀yà rẹ ti ṣi Ejibiti lọ́nà.
14 Jehova nĩwe ũmaitĩrĩirie roho wa kĩrigiicano; matũmaga andũ a Misiri matũgũũge mawĩra-inĩ mothe marĩa marutaga, o ta ũrĩa mũrĩĩu atũgũũgaga matahĩko-inĩ make.
Olúwa ti da ẹ̀mí òòyì sínú wọn; wọ́n mú Ejibiti ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n nínú ohun gbogbo tí ó ń ṣe, gẹ́gẹ́ bí ọ̀mùtí ti í ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n nínú èébì rẹ̀.
15 Gũtirĩ wĩra ũngĩrutwo bũrũri-inĩ wa Misiri: gũtirĩ wĩra ũngĩrutwo nĩ mũtwe kana mũtingʼoe, kana rũhonge rwa mũnathi, kana ithanjĩ.
Kò sí ohun tí Ejibiti le ṣe— orí tàbí ìrù, ọ̀wá ọ̀pẹ tàbí koríko odò.
16 Mũthenya ũcio-rĩ, andũ a Misiri makahaana o ta andũ-a-nja. Makainaina nĩ guoya mona guoko kwa Jehova Mwene-Hinya-Wothe kwambararĩtio kũmookĩrĩre.
Ní ọjọ́ náà ni àwọn ará Ejibiti yóò dàbí obìnrin. Wọn yóò gbọ̀n jìnnìjìnnì pẹ̀lú ẹ̀rù nítorí ọwọ́ Olúwa àwọn ọmọ-ogun tí a gbé sókè sí wọn.
17 Naguo bũrũri wa Juda ũkaguoyohia andũ a Misiri; na mũndũ o wothe ũkaagweterwo ũhoro wa Juda nĩagetigĩra, nĩ ũndũ wa maũndũ marĩa Jehova Mwene-Hinya-Wothe aciirĩire gwĩka amokĩrĩre.
Ilẹ̀ Juda yóò sì di ẹ̀rù fún Ejibiti; gbogbo àwọn tí a bá ti dárúkọ Juda létí wọn ni yóò wárìrì, nítorí ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun gbèrò láti ṣe sí wọn.
18 Mũthenya ũcio matũũra matano ma bũrũri wa Misiri makaaragia rũthiomi rwa Kaanani, makĩĩhĩtaga atĩ marĩtungatagĩra Jehova Mwene-Hinya-Wothe. Na itũũra rĩmwe rĩamo rĩgeetagwo Itũũra Inene rĩa Mwanangĩko.
Ní ọjọ́ náà ìlú márùn-ún ní ilẹ̀ Ejibiti yóò sọ èdè àwọn ará Kenaani, wọn yóò sì búra àtìlẹ́yìn fún Olúwa àwọn ọmọ-ogun. Ọ̀kan nínú wọn ni a ó sì máa pè ní ìlú ìparun.
19 Mũthenya ũcio-rĩ, nĩgũkagĩa na kĩgongona kĩa Jehova o kũu gatagatĩ ka bũrũri wa Misiri, na kũhaandwo ihiga rĩa kĩririkano kĩa Jehova mĩhaka-inĩ yakuo.
Ní ọjọ́ náà pẹpẹ kan yóò wà fún Olúwa ní àárín gbùngbùn Ejibiti, àti ọ̀wọ́n kan fún Olúwa ní etí bodè rẹ̀.
20 Ihiga rĩu rĩgaatuĩka kĩmenyithia na mũira wa maũndũ marĩa Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekĩte thĩinĩ wa bũrũri ũcio wa Misiri. Rĩrĩa magaakaĩra Jehova amateithie nĩ ũndũ wa andũ arĩa mamahinyagĩrĩria-rĩ, nĩakamatũmĩra mũhonokia na mũmagitĩri, nake nĩakamahonokia.
Yóò sì jẹ́ àmì àti ẹ̀rí sí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ní ilẹ̀ Ejibiti. Nígbà tí wọ́n bá ké pe Olúwa nítorí àwọn aninilára wọn, yóò rán olùgbàlà àti olùgbèjà kan sí wọn tí yóò sì gbà wọ́n sílẹ̀.
21 Nĩ ũndũ ũcio Jehova nĩakemenyithania kũrĩ andũ a Misiri, na mũthenya ũcio nĩmagakũũrana Jehova. Makaamũhooyaga makĩmũrutagĩra magongona na maruta ma mũtu: na ningĩ makehĩtaga mĩĩhĩtwa marĩ mbere ya Jehova na mamĩhingagie.
Báyìí ni Olúwa yóò sọ ara rẹ̀ di mí mọ̀ fún àwọn ará Ejibiti àti ní ọjọ́ náà ni wọn yóò gba Olúwa gbọ́. Wọn yóò sìn ín pẹ̀lú ẹbọ ọrẹ ìyẹ̀fun, wọn yóò jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún Olúwa wọn yóò sì mú un ṣẹ.
22 Jehova nĩakahũũra bũrũri wa Misiri na mũthiro, amahũũre acooke amahonie. Nao nĩmagacookerera Jehova, nake nĩagathikĩrĩria gũthaithana kwao na amahonie.
Olúwa yóò fi àjàkálẹ̀-ààrùn kan bá Ejibiti jà; yóò bá wọn jà yóò sì tún wò wọ́n sàn. Wọn yóò yípadà sí Olúwa, Òun yóò sì gbọ́ ẹ̀bẹ̀ wọn yóò sì wò wọ́n sàn.
23 Mũthenya ũcio nĩgũkagĩa njĩra njariĩ yumĩte bũrũri wa Misiri ĩgakinya Ashuri. Andũ a Ashuri nĩmagathiiaga Misiri, na o andũ a Misiri mathiiage Ashuri. Andũ a Misiri na andũ a Ashuri nĩmakahooyaga hamwe.
Ní ọjọ́ náà òpópónà kan yóò wá láti Ejibiti lọ sí Asiria. Àwọn ará Asiria yóò lọ sí Ejibiti àti àwọn ará Ejibiti lọ sí Asiria. Àwọn ará Ejibiti àti ará Asiria yóò jọ́sìn papọ̀.
24 Mũthenya ũcio bũrũri wa Isiraeli ũgaatuĩka wa gatatũ, hamwe na Misiri na Ashuri, nao nĩmagatũma thĩ yothe ĩrathimwo.
Ní ọjọ́ náà Israẹli yóò di ẹ̀kẹta pẹ̀lú Ejibiti àti Asiria, àní orísun ìbùkún ní ilẹ̀ ayé.
25 Jehova Mwene-Hinya-Wothe nĩakamarathima akiugaga atĩrĩ, “Kũrathimwo-rĩ, nĩ andũ akwa a Misiri, o na Aashuri arĩa ndeyũmbĩire, na Isiraeli igai rĩakwa.”
Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò bùkún wọn yóò wí pé, “Ìbùkún ni fún Ejibiti ènìyàn mi, Asiria iṣẹ́ ọwọ́ mi, àti Israẹli ìní mi.”

< Isaia 19 >