< Hosea 12 >
1 Efiraimu arĩĩaga rũhuho; ahanyũkagia rũhuho rwa mwena wa irathĩro mũthenya wothe, na akaingĩhia maheeni na haaro. Agĩĩaga na kĩrĩkanĩro na Ashuri, na agatũmana maguta ma mĩtamaiyũ matwarwo bũrũri wa Misiri.
Efraimu ń jẹ afẹ́fẹ́; o ń lépa afẹ́fẹ́ ìwọ̀-oòrùn ní gbogbo ọjọ́. O sì ń gbèrú nínú irọ́ o dá májẹ̀mú pẹ̀lú Asiria o sì fi òróró olifi ránṣẹ́ sí Ejibiti.
2 Jehova arĩ na thitango ekũrehe ya gũũkĩrĩra Juda; nĩakaherithia Jakubu kũringana na njĩra ciake, na amũrĩhe kũringana na ciĩko ciake.
Olúwa ní ẹjọ́ kan tí yóò bá Juda rò, yóò fì ìyà jẹ Jakọbu gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ̀ yóò sì sán fún un gẹ́gẹ́ bí i ìṣe rẹ̀.
3 Arĩ nda ya nyina nĩanyiitire ndiira ya mũrũ wa nyina; aatuĩka mũndũ mũgima-rĩ, nĩagianire na Ngai.
Láti inú oyún ni ó ti di arákùnrin rẹ̀ mú ni gìgísẹ̀, àti nípa ipá rẹ̀ ó ni agbára pẹ̀lú Ọlọ́run
4 Nĩagianire na mũraika, na akĩmũtooria; akĩrĩra na akĩmũthaitha amũrathime. Aamũkorire Betheli na makĩaranĩria nake kũu:
Ó bá angẹli ja ìjàkadì, ó sì borí rẹ̀, o sọkún, ó sì bẹ̀bẹ̀ fún ojúrere rẹ̀. Ó bá Olúwa ní Beteli, Ó sì bá a sọ̀rọ̀ níbẹ̀,
5 Jehova Ngai Mwene-Hinya-Wothe, Jehova nĩrĩo rĩĩtwa rĩake rĩrĩa rĩrĩ ngumo.
àní Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun; Olúwa ni orúkọ ìrántí rẹ̀.
6 No rĩrĩ, wee no nginya ũcookerere Ngai waku, na ũtũũrie wendo na kĩhooto, na wetagĩrĩre Ngai waku hĩndĩ ciothe.
Ṣùgbọ́n ìwọ gbọdọ̀ padà sọ́dọ̀ Ọlọ́run rẹ̀; di ìfẹ́ àti ìdájọ́ òdodo mú kí ẹ sì dúró de Ọlọ́run yín nígbà gbogbo.
7 Mwonjorithia ahũthagĩra gĩthimi gĩtarĩ kĩa ma; endaga kũiya na wara.
Oníṣòwò ń lo òsùwọ̀n èké o fẹ́ràn láti rẹ́ ni jẹ.
8 Efiraimu eganaga, akoiga atĩrĩ, “Niĩ ndĩ mũtongu mũno; niĩ nĩnduĩkĩte gĩtonga. No o na ndĩ na ũtonga ũcio wothe, matingĩona waganu kana wĩhia o na ũrĩkũ thĩinĩ wakwa.”
Efraimu gbéraga, “Èmi ní ìní fún ara mi, mo sì ti di ọlọ́rọ̀, pẹ̀lú gbogbo ọrọ̀ mi yìí, wọn kò le ká àìṣedéédéé tàbí ẹ̀ṣẹ̀ kankan mọ́ mi lọ́wọ́.”
9 “Nĩ niĩ Jehova Ngai wanyu, ũrĩa wamũrutire bũrũri wa Misiri; nĩngatũma mũtũũre hema-inĩ rĩngĩ, o ta ũrĩa mwatũũraga matukũ-inĩ ma ciathĩ cianyu iria nyamũre.
“Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ; ẹni tí ó mu ọ jáde wá láti ilẹ̀ Ejibiti; èmi yóò tún mú yín gbé nínú àgọ́ bí i ọjọ́ àjọ̀dún tí a yàn wọ̀n-ọn-nì.
10 Nĩndarĩirie anabii, ngĩmahe cioneki nyingĩ, na ngĩheana ngerekano na tũnua twao.”
Mo sọ fún àwọn wòlíì, mo fi ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìran hàn wọ́n mo sì pa òwe láti ẹnu wòlíì wọn.”
11 Gileadi-rĩ, nĩ kũrĩ waganu? Andũ akuo nĩ a tũhũ! Nĩmarutagĩra igongona rĩa ndegwa kũu Giligali? Igongona ciao igaatuĩka ta hĩba cia mahiga irĩ mũgũnda-inĩ mũciimbe.
Gileadi ha burú bí? Àwọn ènìyàn rẹ̀ jẹ́ asán. Ǹjẹ́ wọ́n ń fi akọ màlúù rú ẹbọ ní Gilgali? Gbogbo pẹpẹ wọ́n sì dàbí ebè nínú aporo oko.
12 Jakubu nĩorĩire bũrũri wa Aramu; Isiraeli aatungatire nĩguo egĩĩre na mũtumia, na nĩgeetha amũgũre-rĩ, aarĩithirie ngʼondu.
Jakọbu sálọ si orílẹ̀-èdè Aramu; Israẹli sìn kí o tó fẹ́ ìyàwó ó ṣe ìtọ́jú ẹran láti fi san owó ìyàwó.
13 Jehova aahũthĩrire mũnabii kũruta Isiraeli kuuma bũrũri wa Misiri, na akĩmũmenyerera na guoko kwa mũnabii.
Olúwa lo wòlíì kan láti mú Israẹli jáde wá láti Ejibiti, nípasẹ̀ wòlíì kan ó ṣe ìtọ́jú rẹ̀.
14 No Efiraimu nĩatũmĩte Jehova arakare mũno. Mwathani wake nĩagatũma acookererwo nĩ ihĩtia rĩake rĩa ũiti wa thakame, na amũrĩhe nĩ ũndũ wa rũmena rwake.
Ṣùgbọ́n Efraimu ti mú un bínú gidigidi; Olúwa rẹ̀ yóò sì fi ẹ̀bi ìtàjẹ̀ sílẹ̀ sí orí rẹ̀ òun yóò sì san án padà fún un nítorí ìwà ẹ̀gàn an rẹ̀.