< Agalatia 1 >
1 Nĩ niĩ mũtũmwo Paũlũ, na rĩrĩ, ndirĩ mũtũmwo ũtũmĩtwo nĩ andũ o na kana ngatũmwo na njĩra ya mũndũ, no ndũmĩtwo nĩ Jesũ Kristũ na Ngai Ithe witũ, ũrĩa wamũriũkirie kuuma kũrĩ arĩa akuũ.
Paulu, aposteli tí a rán kì í ṣe láti ọ̀dọ̀ ènìyàn wá, tàbí nípa ènìyàn, ṣùgbọ́n nípa Jesu Kristi àti Ọlọ́run Baba, ẹni tí ó jí i dìde kúrò nínú òkú.
2 Niĩ hamwe na ariũ na aarĩ a Ithe witũ othe arĩa tũrĩ nao, nĩ ithuĩ tũramũtũmĩra marũa maya, Kũrĩ inyuĩ andũ a makanitha ma Galatia:
Àti gbogbo àwọn arákùnrin tí ó wà pẹ̀lú mi, Sí àwọn ìjọ ní Galatia:
3 Mũrogĩa na wega na thayũ iria ciumĩte kũrĩ Ngai Ithe witũ, o na kũrĩ Mwathani Jesũ Kristũ,
Oore-ọ̀fẹ́ sí yín àti àlàáfíà láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Baba wá àti Jesu Kristi Olúwa,
4 ũrĩa werutire nĩ ũndũ wa mehia maitũ nĩguo atũhonokie kuuma kũrĩ mahinda maya tũrĩ, marĩa maiyũrĩtwo nĩ maũndũ mooru, kũringana na wendi wa Ngai Ithe witũ, (aiōn )
ẹni tí ó fi òun tìkára rẹ̀ dípò ẹ̀ṣẹ̀ wa, kí ó lè gbà wá kúrò nínú ayé búburú ìsinsin yìí, gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ Ọlọ́run àti Baba wa, (aiōn )
5 nake arotũũra akumagio nginya tene na tene. Ameni. (aiōn )
ẹni tí ògo wà fún láé àti láéláé. Àmín. (aiōn )
6 Niĩ nĩkũgega ndĩragega nĩ ũndũ wa ũrĩa mũrahiũha gũtigana na ũrĩa wamwĩtire na ũndũ wa wega wa Kristũ, mũkagarũrũkĩra ũhoro mwega wa mũthemba ũngĩ,
Ó yà mi lẹ́nu pé ẹ tètè yapa kúrò lọ́dọ̀ ẹni tí ó pè yín sínú oore-ọ̀fẹ́ Kristi, sí ìyìnrere mìíràn.
7 naguo ti Ũhoro-ũrĩa-Mwega o na atĩa. No nĩ kũrĩ andũ maramũhĩngĩĩca makĩenda gũthũkia Ũhoro-ũrĩa-Mwega wa Kristũ.
Nítòótọ́, kò sí ìyìnrere mìíràn bí ó tilẹ̀ ṣe pé àwọn kan wà, tí ń yọ yín lẹ́nu, tí wọ́n sì ń fẹ́ yí ìyìnrere Kristi padà.
8 No rĩrĩ, o na kũngĩkorwo nĩ ithuĩ o na kana mũraika uumĩte igũrũ, ũngĩmũhunjĩria ũhoro mwega ũngĩ tiga ũrĩa twamũhunjĩirie-rĩ, mũndũ ũcio aronyiitwo nĩ kĩrumi nginya tene!
Ṣùgbọ́n bí ó ṣe àwa ni tàbí angẹli kan láti ọ̀run wá, ni ó bá wàásù ìyìnrere mìíràn fún yín ju èyí tí a tí wàásù rẹ̀ fún yín lọ, jẹ́ kí ó di ẹni ìfibú títí láéláé!
9 O ta ũrĩa tũmwĩrĩte, o na rĩu nĩ nguuga o rĩngĩ atĩrĩ, mũndũ o wothe angĩmũhunjĩria ũhoro mwega ũngĩ tiga ũrĩa mwetĩkirie-rĩ, aronyiitwo nĩ kĩrumi nginya tene!
Bí àwa ti wí ṣáájú, bẹ́ẹ̀ ni mo sì tún wí nísinsin yìí pé, bí ẹnìkan bá wàásù ìyìnrere mìíràn fún yín ju èyí tí ẹ̀yin tí gbà lọ, jẹ́ kí ó di ẹni ìfibú títí láéláé!
10 Atĩrĩrĩ, ngiuga ũguo-rĩ, kaĩ arĩ andũ ndĩrenda kwĩyendithia kũrĩ o, kana nĩ kũrĩ Ngai? Kana hihi nĩ andũ ndĩrenda gũkenia? Korwo nĩ andũ ngeragia gũkenia-rĩ, ndingĩkorwo ndĩ ndungata ya Kristũ.
Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ènìyàn ni èmi ń wá ojúrere rẹ̀ ní tàbí Ọlọ́run? Tàbí ènìyàn ni èmi ń fẹ́ láti wù bí? Bí èmi bá ń fẹ́ láti wu ènìyàn, èmi kò lè jẹ́ ìránṣẹ́ Kristi.
11 Ariũ na aarĩ a Ithe witũ, ngwenda mũmenye atĩ Ũhoro-ũrĩa-Mwega ndamũhunjĩirie ti ũhoro woimanĩte na mũndũ.
Mo fẹ́ kí ẹ mọ̀, ará, pé ìyìnrere tí mo tí wàásù kì í ṣe láti ipa ènìyàn.
12 Ũhoro ũcio ndiaheirwo nĩ mũndũ, o na kana ngĩthomithio nĩ mũndũ; no nĩ kũguũrĩrio ndaguũrĩirio Ũhoro ũcio nĩ Jesũ Kristũ.
N kò gbà á lọ́wọ́ ènìyàn kankan, bẹ́ẹ̀ ni a kò fi kọ́ mi, ṣùgbọ́n mo gbà á nípa ìfihàn láti ọ̀dọ̀ Jesu Kristi.
13 Nĩgũkorwo nĩmũiguĩte ũhoro wa mĩthiĩre yakwa ya tene, ũrĩa ndaatũire njĩkaga ndĩ thĩinĩ wa ndini ya Ayahudi, na ũrĩa ndanyariiraga kanitha wa Ngai na hinya ngĩgeria kũũniina.
Nítorí ẹ̀yin ti gbúròó ìgbé ayé mi nígbà àtijọ́ nínú ìsìn àwọn Júù, bí mo tí ṣe inúnibíni sí ìjọ ènìyàn Ọlọ́run rékọjá ààlà, tí mo sì lépa láti bà á jẹ́.
14 Niĩ ha ũhoro wa maũndũ makoniĩ ndini ya Ayahudi, nĩ ndaathiĩte mbere o na gũkĩra Ayahudi aingĩ a riika rĩakwa na ndaarĩ na kĩyo kĩnene gĩa kũrũmia mĩtugo ya maithe maitũ.
Mo sì ta ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ẹlẹgbẹ́ mi yọ nínú ìsìn àwọn Júù láàrín àwọn ìran mi, mo sì ni ìtara lọ́pọ̀lọ́pọ̀ sì òfin àtọwọ́dọ́wọ́ àwọn baba mi.
15 No rĩrĩ, Ngai ũrĩa wanyamũrire kuuma ndaciarwo, na akĩnjĩta nĩ ũndũ wa wega wake-rĩ, nĩ oonire arĩ wega,
Ṣùgbọ́n nígbà tí ó wú Ọlọ́run ẹni tí ó yà mí sọ́tọ̀ láti inú ìyá mi wá, tí ó sì pé mi nípa oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀.
16 anguũrĩrie Mũriũ nĩgeetha hunjagĩrie andũ-a-Ndũrĩrĩ ũhoro wake; gũtirĩ mũndũ o na ũrĩkũ ndaahoire kĩrĩra,
Láti fi ọmọ rẹ̀ hàn nínú mi, kì èmi lè máa wàásù ìyìnrere rẹ̀ láàrín àwọn aláìkọlà; èmi kò wá ìmọ̀ lọ sọ́dọ̀ ẹnikẹ́ni,
17 o na ndiambatire Jerusalemu kuonana na arĩa maarĩ atũmwo mbere yakwa, no ndathiire bũrũri wa Arabia na ihenya, na thuutha ũcio ngĩcooka Dameski.
bẹ́ẹ̀ ni èmi kò gòkè lọ sì Jerusalẹmu tọ àwọn tí í ṣe aposteli ṣáájú mi, ṣùgbọ́n mo lọ sí Arabia, mo sì tún padà wá sí Damasku.
18 Na rĩrĩ, thuutha wa mĩaka ĩtatũ, nĩndambatire Jerusalemu nĩguo tũkamenyane na Petero, na ngĩikara nake matukũ ikũmi na matano.
Lẹ́yìn ọdún mẹ́ta, nígbà náà ni mo gòkè lọ sì Jerusalẹmu láti lọ kì Peteru, mo sì gbé ọ̀dọ̀ rẹ̀ ní ìjọ mẹ́ẹ̀ẹ́dógún,
19 Tũtionanire na atũmwo acio angĩ, tiga o Jakubu, mũrũ wa nyina na Mwathani.
èmi kò ri ẹlòmíràn nínú àwọn tí ó jẹ́ aposteli, bí kò ṣe Jakọbu arákùnrin Olúwa.
20 Ũhoro ũyũ ndĩramwandĩkĩra, ndĩramwĩra ndĩ mbere ya Ngai atĩ nĩ wa ma na ndiraheenania.
Nǹkan tí èmi ń kọ̀wé sí yín yìí, kíyèsi i, níwájú Ọlọ́run èmi kò ṣèké.
21 Thuutha ũcio nĩndacookire ngĩthiĩ Suriata na Kilikia.
Lẹ́yìn náà mo sì wá sí agbègbè Siria àti ti Kilikia.
22 Niĩ mwene ndiamenyekete nĩ makanitha ma Judea marĩa marĩ thĩinĩ wa Kristũ.
Mo sì jẹ́ ẹni tí a kò mọ̀ lójú fún àwọn ìjọ tí ó wà nínú Kristi ni Judea.
23 No kũigua maiguaga atĩrĩ, “Mũndũ ũrĩa ũratũire atũnyariiraga rĩu nĩwe ũrahunjia wĩtĩkio ũrĩa aageragia kũniina mbere ĩyo.”
Wọ́n kàn gbọ́ ìròyìn wí pé, “Ẹni tí ó tí ń ṣe inúnibíni sí wa rí, ní ìsinsin yìí ti ń wàásù ìgbàgbọ́ náà tí ó ti gbìyànjú láti bàjẹ́ nígbà kan rí.”
24 Nao makĩgooca Ngai nĩ ũndũ wakwa.
Wọ́n sì yin Ọlọ́run lógo nítorí mi.