< Ezekieli 9 >

1 Ningĩ ngĩigua agĩĩtana na mũgambo mũnene, akiuga atĩrĩ, “Rehei arangĩri a itũũra inene haha, o mũndũ arĩ na itharaita rĩa mbaara guoko-inĩ.”
Mo gbọ́ ti ó kígbe ní ohùn rara pé, “Mú àwọn olùṣọ́ ìlú súnmọ́ itòsí, kí olúkúlùkù wọn mú ohun ìjà olóró lọ́wọ́.”
2 Na niĩ ngĩona andũ atandatũ magĩũka moimĩte mwena wa kĩhingo kĩa rũgongo, kĩrĩa kĩrorete mwena wa gathigathini, o mũndũ arĩ na kĩndũ gĩa kũũragana guoko-inĩ. Makĩrehane na mũndũ ũngĩ ũmwe wehumbĩte nguo cia gatani na eyohete indo cia kwandĩka njohero. Nao magĩtoonya makĩrũgama mwena-inĩ wa kĩgongona kĩrĩa gĩa gĩcango.
Lójú ẹsẹ̀ ni ọkùnrin mẹ́fà jáde láti ẹnu-ọ̀nà òkè tó kọjú sí ìhà àríwá, olúkúlùkù pẹ̀lú ohun ìjà olóró lọ́wọ́ wọn. Ọkùnrin kan tó wọ aṣọ funfun gbòò wa láàrín wọn, pẹ̀lú ohun ìkọ̀wé lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀. Gbogbo wọn sì dúró lẹ́gbẹ̀ẹ́ pẹpẹ idẹ.
3 Na rĩrĩ, riiri wa Ngai wa Isiraeli ũkĩambata uumĩte igũrũ rĩa makerubi, harĩa warĩ mbere, ũgĩthiĩ hingĩro-inĩ ya hekarũ. Ningĩ Jehova agĩĩta mũndũ ũcio wehumbĩte nguo cia gatani, o ũcio weyohete indo cia kwandĩka njohero,
Ògo Ọlọ́run Israẹli sì gòkè kúrò lórí kérúbù, níbi tó wà tẹ́lẹ̀ lọ sí ibi ìloro tẹmpili. Nígbà náà ni Olúwa pe ọkùnrin tó wọ aṣọ funfun náà tí ó sì ní ohun ìkọ̀wé lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀.
4 akĩmwĩra atĩrĩ, “Thiĩ ũtuĩkanie itũũra inene rĩa Jerusalemu, na wĩkĩre rũũri ithiithi cia arĩa marĩ na kĩeha, na magacakaya nĩ ũndũ wa maũndũ mothe marĩ magigi marĩa mekagwo kũu thĩinĩ warĩo.”
Ó sì sọ fún un pé, “La àárín ìlú Jerusalẹmu já, kí ìwọ sì fi àmì síwájú orí gbogbo àwọn tó ń kẹ́dùn, tó sì ń sọkún nítorí ohun ìríra tí wọn ń ṣe láàrín rẹ̀.”
5 O thikĩrĩirie ũguo, akĩĩra acio angĩ atĩrĩ, “Mũrũmĩrĩrei, mũtuĩkanĩrie itũũra rĩu inene mũũragane mũtekũiguanĩra tha kana gũcaayanĩra.
Bí mo ṣe ń fetí sí èyí, O tún sọ fún àwọn yòókù pé, “Tẹ̀lé ọkùnrin náà lọ sí àárín ìlú láti pa láì dá sí àti láì ṣàánú rárá.
6 Ũragai athuuri, na aanake na airĩtu, na andũ-a-nja na ciana, no mũtikahutie mũndũ o na ũrĩkũ mwĩkĩre rũũri rũu. Ambĩrĩriai o haha hakwa haamũre.” Nĩ ũndũ ũcio makĩambĩrĩria na athuuri arĩa maarĩ hau mbere ya hekarũ.
Ẹ pa arúgbó àti ọ̀dọ́mọkùnrin, ẹ pa ọlọ́mọge, obìnrin àti ọmọ kéékèèké, ṣùgbọ́n ẹ má ṣe fi ọwọ́ kan àwọn tó ní àmì. Ẹ bẹ̀rẹ̀ láti ibi mímọ́.” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ láti ọ̀dọ̀ àwọn àgbàgbà tó wà níwájú tẹmpili.
7 Ningĩ akĩmeera atĩrĩ, “Thaahiai hekarũ ĩno na mũiyũrie nja ciayo andũ arĩa moragĩtwo. Thiĩi!” Nĩ ũndũ ũcio makiumagara, makĩambĩrĩria kũũragana kũu itũũra-inĩ inene.
Nígbà náà lo sọ fún wọn pé, “Ẹ sọ tẹmpili náà di àìmọ́, kí òkú sì kún àgbàlá náà. Ẹ lọ!” Wọ́n jáde síta, wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí í pa ènìyàn láàrín ìlú.
8 Hĩndĩ ĩrĩa mooraganaga niĩ ngĩtigwo ndĩ nyiki, ngĩĩgũithia, ngĩturumithia ũthiũ thĩ, ngĩrĩra, ngĩũria atĩrĩ, “Hĩ, Mwathani Jehova! Anga nĩũkũniina matigari mothe ma Isiraeli hĩndĩ ĩno ya gũitĩrĩria Jerusalemu mangʼũrĩ maku?”
Èmi nìkan ló ṣẹ́kù nígbà tí wọ́n lọ pa àwọn ènìyàn, mo dójú mi bolẹ̀, mo kígbe pé, “Háà! Olúwa Olódùmarè! Ìwọ yóò ha pa ìyókù Israẹli nípa dída ìbínú gbígbóná rẹ sórí Jerusalẹmu?”
9 Nake akĩnjookeria atĩrĩ, “Mehia ma nyũmba ya Isiraeli na ya Juda nĩ maingĩ magakĩra; bũrũri ũiyũrĩte ũiti wa thakame, narĩo itũũra inene rĩiyũrĩte ũhotomia wa kĩhooto. Moigaga atĩrĩ, ‘Jehova nĩatiganĩirie bũrũri ũyũ; Jehova ndarona.’
Ó dá mi lóhùn pé, “Ẹ̀ṣẹ̀ ilé Israẹli àti Juda pọ gidigidi; ilé wọn kún fún ìtàjẹ̀ sílẹ̀ àti àìṣòótọ́. Wọ́n ní, ‘Olúwa tí kọ ilẹ̀ náà sílẹ̀; Olúwa kò sì rí wa.’
10 Nĩ ũndũ ũcio-rĩ, Niĩ ndigacooka kũmaiguĩra tha kana kũmacaaĩra, no nĩngamacookereria ũrĩa mekĩte.”
Nítorí náà, èmi kò ní wò wọ́n pẹ̀lú àánú, èmi kò sì ní dá wọn sí, ṣùgbọ́n Èmi yóò dá ohun tí wọ́n ti ṣe padà sórí wọn.”
11 Ningĩ mũndũ ũcio wehumbĩte nguo cia gatani, na akeoha indo cia wandĩki njohero, agĩcookia ndũmĩrĩri, akiuga atĩrĩ, “Nĩnjĩkĩte o ta ũrĩa wathanire.”
Ọkùnrin tí ó wọ aṣọ ọ̀gbọ̀, tí ó ní ìwo tàdáwà ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀ ròyìn pé, “Mo ti ṣe gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti pàṣẹ fún mi.”

< Ezekieli 9 >