< Ezekieli 8 >
1 Mwaka-inĩ wa ĩtandatũ, mweri wa ĩtandatũ, mũthenya wa gatano, rĩrĩa ndaikarĩte gwakwa nyũmba nao athuuri a Juda magaikara mbere yakwa-rĩ, guoko kwa Mwathani Jehova gũgĩũka igũrũ rĩakwa.
Ní ọjọ́ karùn-ún, oṣù kẹfà ọdún kẹfà bí mo ṣe jókòó nílé mi pẹ̀lú àwọn àgbàgbà Juda níwájú mi, ọwọ́ Olúwa Olódùmarè bà lé mi níbẹ̀.
2 Ngĩrora, ngĩona mũhiano ta wa mũndũ. Kuuma harĩa honekaga taarĩ njohero yake gũcooka na thĩ aahaanaga ta mwaki, na kuuma hau gũcooka na igũrũ oonekaga akĩhenia ta kĩgera kĩraakana.
Nígbà tí mo wò, mo rí ohun kan tí ó jọ ènìyàn. Láti ibi ìbàdí rẹ lọ sísàlẹ̀ dàbí iná, láti ibi ìbàdí yìí sókè sì mọ́lẹ̀ bí idẹ tó ń kọ mọ̀nà.
3 Nĩatambũrũkirie kĩndũ kĩahaanaga ta guoko na akĩnjoya anyiitĩte njuĩrĩ cia mũtwe wakwa. Roho akĩnjoya na-igũrũ rĩera-inĩ, na akĩndwara Jerusalemu, ndĩ cioneki-inĩ cia Ngai, nginya mũrango-inĩ wa kĩhingo gĩa gathigathini kĩa nja ya na thĩinĩ, harĩa mũhianano ũrĩa ũtũmaga Ngai aigue ũiru warũngiĩ.
Ó na ohun tó dàbí ọwọ́ jáde, ó fi gba mi ní irun orí mú, Ẹ̀mí sì gbé mi sókè sí agbede-méjì ayé àti ọ̀run, ó sì mú mi lọ rí ìran Ọlọ́run, mo sì lọ sí Jerusalẹmu, ṣí ìlẹ̀kùn ẹnu-ọ̀nà òde àríwá níbi tí ère owú tí ó ń mú ni bínú wá níwájú mi.
4 Na hau mbere yakwa nĩho riiri wa Ngai wa Isiraeli warĩ, o ta ũrĩa ndoonete kĩoneki-inĩ werũ-inĩ.
Sì kíyèsi i, ògo Ọlọ́run Israẹli wà níbẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ìran ti mo rí ni pẹ̀tẹ́lẹ̀.
5 Ningĩ akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Mũrũ wa mũndũ, rora mwena wa gathigathini.” Nĩ ũndũ ũcio ngĩrora, na hau itoonyero-inĩ rĩa mwena wa gathigathini wa kĩhingo gĩa kĩgongona, ngĩona mũhianano ũcio ũtũmaga Ngai aigue ũiru.
Ó sì sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, gbójú sókè sí ìhà àríwá.” Èmi náà sì gbójú sókè sí ìhà àríwá mo sì rí ère tí ó ń mú ni jowú ní ẹnu-ọ̀nà ibi pẹpẹ.
6 Nake akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Mũrũ wa mũndũ, nĩũrona ũrĩa mareeka; maũndũ marĩ magigi biũ marĩa andũ a nyũmba ya Isiraeli marekĩra haha, maũndũ ma kũndindĩka kũraya na handũ-hakwa-harĩa-haamũre? No wee-rĩ, nĩũkuona maũndũ o na marĩ magigi makĩria.”
Ó sì wí fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, ṣé o rí ohun tí wọ́n ń ṣe ohun ìríra ńlá tí ilé Israẹli ń ṣe, láti lé mi jìnnà réré sí ibi mímọ́ mi? Ṣùgbọ́n ìwọ yóò tún rí àwọn ìríra ńlá tó tóbi jù èyí lọ.”
7 Ningĩ akĩndehe itoonyero-inĩ rĩa nja ĩyo. Ngĩrora ngĩona irima rũthingo-inĩ.
Ó mú mi wá sí ẹnu-ọ̀nà àgbàlá. Mo wò ó, mo sì rí ihò kan lẹ́gbẹ̀ẹ́ ògiri.
8 Akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Mũrũ wa mũndũ, aramia irima rĩu rĩrĩ rũthingo-inĩ.” Rĩrĩa ndaaramirie irima rĩu, ngĩona nĩ haarĩ na mũrango.
Nígbà náà ló sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, gbẹ́ inú ògiri náà,” nígbà tí mo sì gbẹ́ inú ògiri, mo rí ìlẹ̀kùn kan.
9 Ningĩ akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Toonya thĩinĩ wĩonere maũndũ marĩ magigi marĩa mareka kuo.”
Ó sì wí fún mi pé, “Wọlé kí ìwọ kí ó rí ohun ìríra búburú tí wọ́n ń ṣe níbẹ̀.”
10 Nĩ ũndũ ũcio ngĩtoonya kuo, ngĩrora ngĩona thingo-inĩ gũkururĩtwo mĩthemba yothe ya indo iria ikurumaga, na ya nyamũ ciothe iria irĩ mũgiro, na ya mĩhianano yothe ya andũ a nyũmba ya Isiraeli.
Mo wọlé, mo sì rí àwòrán oríṣìíríṣìí ẹranko tí ń fà nílẹ̀ àti àwọn ẹranko ìríra àti gbogbo òrìṣà ilẹ̀ Israẹli tí wọ́n yà sára ògiri.
11 Hau mbere yacio nĩ haarũgamĩte athuuri mĩrongo mũgwanja a nyũmba ya Isiraeli, nake Jazania mũrũ wa Shafani akarũgama gatagatĩ-inĩ kao. O ũmwe wao aanyiitĩte rũgĩo rwa gũcinĩra ũbumba, nayo ndogo ĩrĩ na mũtararĩko mwega wa ũbumba nĩyatoogaga na igũrũ.
Níwájú wọn ni àádọ́rin ọkùnrin tó jẹ́ àgbàgbà ilé Israẹli dúró sí, Jaaṣaniah ọmọ Ṣafani sì dúró sí àárín wọn. Ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn sì mú àwo tùràrí lọ́wọ́, òórùn sì ń tú jáde.
12 Nake akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Mũrũ wa mũndũ, nĩwona maũndũ marĩa athuuri a nyũmba ya Isiraeli marekĩra nduma-inĩ, o ũmwe wao arĩ ihooero-inĩ rĩa mũhianano wake? Moigaga atĩrĩ, ‘Jehova ndatuonaga; Jehova nĩatiganĩirie bũrũri ũyũ.’”
Ó sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, ṣé o ti rí ohun tí àwọn àgbàgbà ilé Israẹli ń ṣe nínú òkùnkùn, olúkúlùkù ní yàrá òrìṣà rẹ̀? Wọ́n ní, ‘Olúwa kò rí wa; Olúwa ti kọ̀ ilé náà sílẹ̀.’”
13 Ningĩ akiuga atĩrĩ, “Wee-rĩ, nĩũkũmona magĩĩka maũndũ o na marĩ magigi makĩria.”
Ó tún sọ fún mi pé, “Ìwọ yóò rí wọn tí wọ́n ń ṣe àwọn ohun ìríra tó burú jù bẹ́ẹ̀ lọ.”
14 Ningĩ akĩndehe itoonyero-inĩ rĩa kĩhingo gĩa gathigathini kĩa nyũmba ya Jehova, na niĩ ngĩona andũ-a-nja maikarĩte thĩ ho magĩcakaĩra Tamuzu.
Ó mú mi wá sí ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa tó wà ní ìhà àríwá, mo sì rí àwọn obìnrin tó jókòó, tí wọ́n sí ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa tó wà ní ìhà àríwá, mo sì rí àwọn obìnrin tó jókòó, tí wọ́n sì ń ṣọ̀fọ̀ fún Tamusi.
15 Nake akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Mũrũ wa mũndũ, nĩũrona maũndũ maya? Nĩũkuona maũndũ o na marĩ magigi mũno gũkĩra maya.”
Ó sọ fún mi pé, “Ṣé ìwọ rí báyìí, ọmọ ènìyàn? Ìwọ yóò tún rí ìríra tó ga jù èyí lọ.”
16 Ningĩ akĩndoonyia nja ya na thĩinĩ ya nyũmba ya Jehova, na hau itoonyero-inĩ rĩa hekarũ, gatagatĩ ga gĩthaku na kĩgongona-rĩ, haarĩ arũme ta mĩrongo ĩĩrĩ na atano. Maahutatĩire hekarũ ya Jehova, makaroria mothiũ mao mwena wa irathĩro, makainamagĩrĩra riũa marĩhooe marorete na kũu mwena wa irathĩro.
Ó mú mi wá sí ibi àgbàlá ilé Olúwa, ní ẹnu-ọ̀nà tẹmpili Olúwa, láàrín ìloro àti pẹpẹ, ni ìwọ̀n ọkùnrin mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n wà, tí wọ́n kẹ́yìn sí tẹmpili Olúwa tí wọn sì kọjú sí ìlà-oòrùn, wọ́n sì ń foríbalẹ̀ fún oòrùn ní apá ìlà-oòrùn.
17 Nake akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Mũrũ wa mũndũ, nĩwona ũguo? Anga ũcio nĩ ũndũ mũhũthũ andũ acio a nyũmba ya Juda gwĩka maũndũ marĩ magigi ta macio marekĩra haha? No nginya maiyũrie maũndũ ma ũhinya bũrũri na mandakaragie hĩndĩ ciothe? Ta marore magĩĩkĩra tũhonge maniũrũ mao!
Ó sì wí fún mi, “Ṣé ìwọ ti rí èyí ọmọ ènìyàn? Ǹjẹ́ ohun kékeré ni fún ilé Juda láti ṣe àwọn ohun ìríra tí wọn ń ṣe níbi yìí? Ṣé o tún yẹ kí wọ́n fi ìwà ipá kún ilẹ̀ kí wọn sì máa mú mi bínú ní gbogbo ìgbà? Wò wọn bi wọn ṣe n fi ẹ̀ka wọn sínú inú wọn.
18 Nĩ ũndũ ũcio niĩ nĩngameka maũndũ na marakara; ndikamaiguĩra tha kana ndĩmacaaĩre. O na mangĩkaanĩrĩra matũ-inĩ makwa, ndikamathikĩrĩria.”
Nítorí náà, èmi yóò fi ìbínú bá wọn wí; èmi kò ní i dá wọn sí bẹ́ẹ̀ ni èmi kò sì ní fojú àánú wò wọ́n. Bí wọ́n tilẹ̀ ń pariwo sí mi létí, èmi kò ní fetí sí wọn.”