< Ezekieli 46 >

1 “‘Mwathani Jehova ekuuga ũũ: Kĩhingo kĩa nja ya na thĩinĩ kĩrĩa kĩrorete irathĩro kĩrĩikaraga kĩhingĩtwo mĩthenya ĩtandatũ ĩrĩa ya kũrutwo wĩra, no mũthenya wa Thabatũ na mũthenya wa Karũgamo ka Mweri nĩkĩrĩhingũragwo.
“‘Èyí yìí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí, ẹnu-ọ̀nà àgbàlá ti inú tí ó dojúkọ ìhà ìlà-oòrùn ni kí a tì pa fún ọjọ́ mẹ́fà tí a fi ń ṣiṣẹ́, ṣùgbọ́n ní ọjọ́ ìsinmi àti ní ọjọ́ oṣù tuntun ni kí a ṣí i.
2 Nake mũnene arĩĩtoonyaga kuo na njĩra ya gĩthaku kĩrĩa gĩa itoonyero, na akarũgama hau gĩtugĩ-inĩ gĩa kĩhingo. Nao athĩnjĩri-Ngai marute igongona rĩa maruta make ma njino, na maruta make ma ngwatanĩro. Arĩĩhooyagĩra hau hingĩro-inĩ ya itoonyero, agacooka akoima nja, no kĩhingo kĩu gĩtikahingwo nginya o hwaĩ-inĩ.
Ọmọ-aládé ni kí ó wọlé láti ìta tí ó kángun sí àbáwọlé ẹnu-ọ̀nà, kí ó sì dúró ní ẹnu-ọ̀nà. Àwọn àlùfáà ni yóò rú ọrẹ ẹbọ sísun rẹ̀ àti ọrẹ ìdàpọ̀. Òun ni yóò jọ́sìn ní ìloro ilé ní ẹnu-ọ̀nà, lẹ́yìn náà ni wọn yóò jáde, ṣùgbọ́n wọn kò ni ti ìlẹ̀kùn títí ìrọ̀lẹ́.
3 Nao andũ a bũrũri ũcio nĩmarĩĩhooyagĩra hau mũromo-inĩ wa kĩhingo kĩu marĩ mbere ya Jehova mĩthenya ya Thabatũ na ya Tũrũgamo twa Mweri.
Ní àwọn ọjọ́ ìsinmi àti àwọn oṣù tuntun ni kí àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà jọ́sìn ní iwájú Olúwa ní àbáwọlé ẹnu-ọ̀nà.
4 Namo maruta ma njino marĩa mũnene ũcio arĩĩrutagĩra Jehova mũthenya wa Thabatũ nĩ tũtũrũme tũtandatũ, na ndũrũme ĩmwe, ciothe ikorwo itarĩ na kaũũgũ.
Ọrẹ ẹbọ sísun tí ọmọ-aládé mú wá fún Olúwa ni ọjọ́ ìsinmi ní láti jẹ́ ọ̀dọ́ àgbò mẹ́fà àti àgbò kan, gbogbo rẹ̀ gbọdọ̀ jẹ́ aláìlábùkù.
5 Narĩo iruta rĩa ngano rĩrĩa rĩakũrutanĩrio na ndũrũme ĩyo rĩrĩkoragwo rĩrĩ rĩa eba ĩmwe, na iruta rĩa ngano rĩa kũrutanĩrio na tũtũrũme tũu rĩrĩkoragwo rĩrĩ rĩingĩ o ta ũrĩa angĩyendera, hamwe na hini ĩmwe ya maguta harĩ o eba ĩmwe.
Ọrẹ ẹbọ jíjẹ tí a mú papọ̀ mọ́ àgbò gbọdọ̀ jẹ́ efa kan, ọrẹ ẹbọ jíjẹ tí a mú pẹ̀lú àwọn ọ̀dọ́-àgùntàn ni kí ó pò gẹ́gẹ́ bí ó bá ṣe fẹ́, papọ̀ mọ hínì òróró kan pẹ̀lú efa kọ̀ọ̀kan.
6 Naguo mũthenya wa Karũgamo ka Mweri arĩĩrutaga ndegwa ĩtarĩ ngũrũ, na tũtũrũme tũtandatũ, na ndũrũme ĩmwe, ciothe itarĩ na kaũũgũ.
Àti ni ọjọ́ oṣù tuntun, ẹgbọrọ màlúù kan àìlábàwọ́n, àti ọ̀dọ́-àgùntàn mẹ́fà, àti àgbò kan: wọn o wà láìlábàwọ́n.
7 Ningĩ nĩarĩĩrutaga iruta rĩa ngano, akaruta eba ĩmwe hamwe na ndegwa ĩyo, na eba ĩmwe hamwe na ndũrũme ĩyo, na akaruta tũtũrũme tũingĩ o ta ũrĩa angĩenda kũruta, hamwe na hini ĩmwe ya maguta harĩ o eba ĩmwe.
Yóò si pèsè ọrẹ ẹbọ jíjẹ efa fun ẹgbọrọ akọ màlúù, àti efa kan fun àgbò kan, àti fun àwọn ọ̀dọ́-àgùntàn gẹ́gẹ́ bi èyí ti ipá rẹ̀ ká, àti hínì òróró kan fún efa kan.
8 Na rĩrĩa mũnene egũtoonya-rĩ, arĩĩtoonyagĩra gĩthaku gĩa itoonyero, na akiuma akoimĩra njĩra o ĩyo.
Nígbà tí ọmọ-aládé bá wọlé, ó gbọdọ̀ gbá àbáwọlé ẹnu-ọ̀nà wọ inú, kí ó sì gba ibẹ̀ jáde.
9 “‘Hĩndĩ ĩrĩa andũ a bũrũri ũcio marĩũkaga mbere ya Jehova mĩthenya ya ciathĩ iria njathane, mũndũ o wothe ũrĩa ũgaatoonyera kĩhingo kĩa mwena wa gathigathini akahooe-rĩ, akiuma akoimagĩra kĩhingo gĩa gũthini; na mũndũ o wothe ũgaatoonyera kĩhingo kĩa mwena wa gũthini, akiuma akoimagĩra kĩhingo gĩa gathigathini. Gũtirĩ mũndũ ũgaacookera kĩhingo kĩrĩa atoonyeire, no mũndũ ariumagĩra kĩhingo kĩrĩa kĩngʼetheire kĩu atoonyeire.
“‘Nígbà tí àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà bá wá síwájú Olúwa ni àwọn àjọ̀dún tí a yàn, ẹnikẹ́ni tí ó bá gba ti ẹnu-ọ̀nà ìhà àríwá wọlé láti jọ́sìn gbọdọ̀ gba ti ẹnu-ọ̀nà ìhà gúúsù jáde; ẹnikẹ́ni tí ó bá gba ti ẹnu-ọ̀nà ìhà gúúsù wọlé yóò gba tí ẹnu-ọ̀nà ìhà àríwá jáde. Kò sí ẹni tí ó gbọdọ̀ gba ibi tí ó bá wọlé jáde, ṣùgbọ́n kí olúkúlùkù gba òdìkejì ẹnu-ọ̀nà tí ó gbà wọlé jáde.
10 Mũnene ũcio arĩkoragwo arĩ hamwe nao, agatoonyaga magĩtoonya, na akoimaga makiuma.
Ọmọ-aládé gbọdọ̀ wà ní àárín wọn, kí ó wọlé nígbà tí wọn bá wọlé, kí ó sì jáde nígbà tí wọn bá jáde.
11 “‘Hĩndĩ ya ciathĩ na ya maruga marĩa matuĩtwo, iruta rĩa ngano rĩrĩkoragwo rĩrĩ eba ĩmwe hamwe na ndegwa, na eba ĩmwe hamwe na ndũrũme, na akaruta tũtũrũme tũingĩ o ta ũrĩa angĩyendera, hamwe na hini ĩmwe ya maguta harĩ o eba ĩmwe.
“‘Níbi àwọn àjọ̀dún àti àwọn àjọ̀dún tí a yàn, ọrẹ ẹbọ jíjẹ gbọdọ̀ jẹ́ efa kan fún ẹgbọrọ akọ màlúù kan, efa kan fún àgbò kan, àti fún àwọn ọ̀dọ́-àgùntàn gẹ́gẹ́ bí ó bá ti wu onílúlùkù, pẹ̀lú òróró hínì kan fún efa kan.
12 Hĩndĩ ĩrĩa mũnene ũcio ekũrutĩra Jehova iruta rĩa kwĩyendera, o na rĩngĩkorwo rĩrĩ iruta rĩa njino kana maruta ma ngwatanĩro, nĩarĩhingũragĩrwo kĩhingo kĩrĩa kĩrorete mwena wa irathĩro. Arĩĩrutaga iruta rĩake rĩa njino kana maruta make ma ngwatanĩro o ta ũrĩa ekaga mũthenya wa Thabatũ. Aarĩkia kũruta oime nja na aarĩkia kuuma, kĩhingo kĩu gĩkaahingwo.
Nígbà tí ọmọ-aládé bá pèsè ọrẹ àtinúwá fún Olúwa yálà ọrẹ ẹbọ sísun tàbí ọrẹ ẹbọ ìdàpọ̀ ojú ọ̀nà tí ó dojúkọ ìhà ìlà-oòrùn ni kí ó wà ni ṣíṣí sílẹ̀ fún un. Òun yóò rú ọrẹ ẹbọ sísun rẹ̀ tàbí ọrẹ ẹbọ ìdàpọ̀ gẹ́gẹ́ bí òun ti ṣe ní ọjọ́ ìsinmi. Lẹ́yìn náà, òun yóò jáde, lẹ́yìn ìgbà tí ó bá jáde tán wọn yóò ti ẹnu-ọ̀nà.
13 “‘O mũthenya nĩũrĩrutaga gatũrũme ka ũkũrũ wa mwaka ũmwe gatarĩ na kaũũgũ nĩ ũndũ wa kũrutĩra Jehova iruta rĩa njino; ũrĩkarutaga rũciinĩ o rũciinĩ.
“‘Ní ojoojúmọ́ ni ìwọ yóò pèsè ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan aláìlábùkù fún ọrẹ ẹbọ sísun sí Olúwa; àràárọ̀ ni ìwọ yóò máa pèsè rẹ̀.
14 Ningĩ hamwe nako nĩũrĩrutaga iruta rĩa ngano rĩa gĩcunjĩ gĩa ithathatũ kĩa eba ĩmwe, na gĩcunjĩ gĩa ithatũ kĩa hini ĩmwe ya maguta ma kũringia mũtu ũcio rũciinĩ o rũciinĩ. Iruta rĩĩrĩ rĩa ngano rĩrĩĩrutagĩrwo Jehova rĩrĩ watho wa gũtũũra.
Ìwọ yóò sì máa pèsè ọrẹ ẹbọ jíjẹ pẹ̀lú rẹ̀ ní àràárọ̀, èyí yóò ni ìdámẹ́fà nínú efa àti ìdámẹ́fà nínú òróró hínì láti fi po ìyẹ̀fun. Gbígbé ọrẹ ẹbọ jíjẹ fún Olúwa jẹ́ ìlànà tí ó wà títí.
15 Nĩ ũndũ ũcio gatũrũme kau, na iruta rĩu rĩa ngano, na maguta macio nĩirĩrutagwo rũciinĩ o rũciinĩ rĩrĩ iruta rĩa njino rĩa hĩndĩ ciothe.
Nítorí náà ọ̀dọ́-àgùntàn àti ọrẹ ẹbọ jíjẹ àti òróró ni wọn yóò pèsè ní àràárọ̀ fún ọrẹ ẹbọ sísun ìgbà gbogbo.
16 “‘Mwathani Jehova ekuuga ũũ: Mũnene ũcio angĩkaahe mwanake ũmwe wake kĩheo kuuma kũrĩ igai rĩake, o na kĩo gĩgaatuĩka kĩa njiaro ciake; gĩgaatuĩka indo ciao iria magaĩirwo.
“‘Èyí yìí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè sọ, tí ọmọ-aládé bá mú ọrẹ láti inú ogún ìní rẹ̀ fún ọ̀kan lára àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, yóò jẹ́ ìní tiwọn nípa ogún jíjẹ.
17 No rĩrĩ, angĩkaahe ndungata ĩmwe yake kĩheo kuuma igai-inĩ rĩake, ndungata ĩyo ĩgaatũũra nakĩo o nginya mwaka wayo wa kuohorwo; hĩndĩ ĩyo kĩheo kĩu nĩgĩgacookerera mũnene ũcio. Igai rĩu rĩake nĩ rĩa ariũ ake oiki; nĩ igai rĩao.
Tí ó bá mú ọrẹ láti inú ogún ìní rẹ̀ fún ọ̀kan lára àwọn ọmọ ọ̀dọ̀, ọmọ le pamọ́ títí di ọdún ìdásílẹ̀, lẹ́yìn náà yóò padà sí ọ̀dọ̀ ọmọ-aládé. Ogún ìní rẹ̀ jẹ́ ti àwọn ọmọ rẹ̀ nìkan; ó jẹ́ tiwọn.
18 Mũthamaki ũcio ndangĩtunya andũ acio magai mao na njĩra ya kũmaingata mehere indo-inĩ ciao. Nĩakahe ariũ ake magai mao kuuma indo-inĩ ciake mwene, nĩguo gũtikanagĩe mũndũ o na ũrĩkũ gatagatĩ-inĩ ka andũ akwa ũkeeherio indo-inĩ ciake.’”
Ọmọ-aládé kò gbọdọ̀ mú nǹkan kan lára ogún ìní àwọn ènìyàn, tàbí mú wọn kúrò níbi ohun ìní wọn. Ó ní láti fi ogún ìní rẹ̀ láti inú ìní rẹ̀ fún àwọn ọmọ rẹ̀, kí a ma ba à ya nǹkan kan kúrò lára ìní rẹ̀.’”
19 Thuutha wa ũguo mũndũ ũcio akĩngereria itoonyero-inĩ rĩa mwena wa kĩhingo gĩa tũnyũmba tũu twamũre tũrĩa twarĩ twa athĩnjĩri-Ngai, tũrĩa twarorete mwena wa gathigathini, na akĩnyonia handũ haarĩ mũthia-inĩ wa mwena wa ithũĩro.
Lẹ́yìn náà ọkùnrin náà mú mi kọjá ní àbáwọlé tí ó wà lẹ́bàá ẹnu-ọ̀nà, sí àwọn yàrá mímọ́ tí ó kọjú sí ìhà àríwá, èyí tí ó jẹ́ tí àwọn àlùfáà, ó sì fi ibi kan hàn mí ní apá ìwọ̀-oòrùn.
20 Nake akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Haha nĩho handũ harĩa athĩnjĩri-Ngai marĩrugagĩra iruta rĩa mahĩtia, na iruta rĩa mehia, na nĩho marĩĩhĩhagĩria iruta rĩa ngano, nĩgeetha matikanamoimie na kũu nja ya nyumĩrĩra, matigatherie andũ namo.”
O sọ fún mi pé, “Èyí yìí ni ibi tí àwọn àlùfáà yóò ti ṣe ọrẹ ẹbọ ìdálẹ́bi àti ọrẹ ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, àti tí wọn yóò ti ṣe ọrẹ ẹbọ jíjẹ, láti má ṣe jẹ́ kí wọn mú wọn wá sí ìta àgbàlá, kí wọn sì ya àwọn ènìyàn sí mímọ́.”
21 Ningĩ agĩcooka akĩndwara nja ĩyo ya nyumĩrĩra, na agĩĩthiũrũrũkia koine-inĩ ciayo inya, na niĩ ngĩona atĩ o koine-inĩ nĩ haarĩ na nja ĩngĩ.
Ó sì mú mi lọ sí ìta àgbàlá, ó sì mú mi yí igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin rẹ̀ ká, mo sì ri àgbàlá mìíràn ní igun kọ̀ọ̀kan.
22 Koine-inĩ icio inya cia nja ya nyumĩrĩra nĩ haarĩ na nja ciarĩ njirigĩre. Ciarĩ na gĩthimo kĩaiganaine kĩa ũraihu wa mĩkono mĩrongo ĩna, na wariĩ wa mĩkono mĩrongo ĩtatũ; o nja ĩmwe ya nja icio ciarĩ koine-inĩ icio inya nĩyaiganaine na ĩrĩa ĩngĩ.
Ní igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin ìta àgbàlá tí ó pẹnu pọ̀, ogójì ìgbọ̀nwọ́ ni gígùn àti ọgbọ̀n ìgbọ̀nwọ́ ní ìbú; àgbàlá kọ̀ọ̀kan ni igun kọ̀ọ̀kan jẹ́ ìwọ̀n kan náà.
23 Gũthiũrũrũka mwena wa na thĩinĩ wa nja icio inya nĩ haarĩ na mwako wa mahiga warĩ na mariiko maakĩtwo mathiũrũrũkĩirie hau rungu rwa mwako ũcio.
Ní agbègbè inú ọ̀kọ̀ọ̀kan nínú àgbàlá náà ni ọwọ́ ilẹ̀ kan wà yíká wọn, a sì ṣe ibi ìdáná si abẹ́ ọwọ́ náà yípo.
24 Nake akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Maya nĩmo mariiko marĩa andũ arĩa matungataga thĩinĩ wa hekarũ marĩrugagĩra indo cia magongona iria irutĩtwo nĩ andũ.”
Ó sì wí fún mi pé, “Ìwọ̀nyí ni àwọn ilé ìdáná níbi tí ó ń ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ nínú tẹmpili yóò ti ṣe ẹbọ fún àwọn ènìyàn.”

< Ezekieli 46 >