< Ezekieli 2 >

1 Nake mũndũ ũcio akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Mũrũ wa mũndũ, wĩrũgamie na magũrũ maku, ngwarĩrie.”
Ó sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, dìde dúró lórí ẹsẹ̀ rẹ. Èmi yóò bá ọ sọ̀rọ̀.”
2 O hĩndĩ ĩyo aanjaragĩria, Roho agĩtoonya thĩinĩ wakwa, akĩnjoya akĩndũgamia, na niĩ ngĩigua akĩnjarĩria.
Bí ó ṣe ń sọ̀rọ̀, ẹ̀mí sì wọ inú mi ó mú mi dúró lórí ẹsẹ̀ mi, mo sì ń gbọ́ tí ó ń bá mi sọ̀rọ̀.
3 Nake akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Mũrũ wa mũndũ, nĩngũgũtũma kũrĩ andũ a Isiraeli, ũthiĩ kũrĩ rũrĩrĩ rũu rũremu, o rũu rũnemeire; ruo rwene o na maithe maaruo rũtũũrĩte rũregete kũnjathĩkĩra nginya ũmũthĩ.
Ó sọ pé, “Ọmọ ènìyàn, mo ń rán ọ sí àwọn ọmọ Israẹli, sí ọlọ̀tẹ̀ orílẹ̀-èdè tí wọ́n ti ṣọ̀tẹ̀ sí mi; àwọn àti baba ńlá wọn ti ṣọ̀tẹ̀ sí mi títí di òní olónìí.
4 Andũ acio ndĩragũtũma kũrĩ o-rĩ, nĩmanyũmĩirie ngoro na makaangʼathĩria. Meere atĩrĩ, ‘Ũũ nĩguo Mwathani Jehova aroiga.’
Àwọn ènìyàn tí mo ń rán ọ sí jẹ́ aláìgbọ́ràn àti ọlọ́kàn líle. Sọ fún wọn pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè wí.’
5 Na rĩrĩ, andũ acio mangĩthikĩrĩria kana marege gũthikĩrĩria, nĩgũkorwo nĩ andũ a nyũmba ya ũremi, nĩmakamenya atĩ nĩhakoretwo na mũnabii gatagatĩ-inĩ kao.
Bí wọn fetísílẹ̀ tàbí wọn kò fetísílẹ̀ nítorí pé wọ́n ọlọ̀tẹ̀ ilé ni wọ́n—wọn yóò mọ̀ pé wòlíì kan wà láàrín wọn.
6 Nawe mũrũ wa mũndũ-rĩ, ndũkametigĩre kana wĩtigĩre ciugo ciao. Ndũgetigĩre, o na akorwo congʼe na mĩigua nĩcigũthiũrũrũkĩirie, na ũikaraga gatagatĩ ga tũngʼaurũ. Ndũgetigĩre ũrĩa mekuuga kana ũmakio nĩo, o na akorwo nĩ andũ a nyũmba ya ũremi.
Àti ìwọ, ọmọ ènìyàn, má ṣe bẹ̀rù wọn tàbí ọ̀rọ̀ ẹnu wọn. Má ṣe bẹ̀rù, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé òṣùṣú àti ẹ̀gún yí ọ ká, tí o sì ń gbé àárín àwọn àkéekèe. Má ṣe bẹ̀rù ohun tí wọ́n ń sọ tàbí bẹ̀rù wọn, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ọlọ̀tẹ̀ ìdílé ni wọ́n.
7 No nginya ũmaarĩrie na ciugo ciakwa, kana nĩmegũthikĩrĩria kana matigũthikĩrĩria, nĩ ũndũ nĩ aremi.
Ìwọ gbọdọ̀ sọ ọ̀rọ̀ mi fún wọn, bí wọ́n gbọ́ bí wọn kọ̀ láti gbọ́ torí pé ọlọ̀tẹ̀ ni wọ́n.
8 No wee mũrũ wa mũndũ-rĩ, thikĩrĩria ũrĩa ngũkwĩra. Ndũkareme ta nyũmba ĩyo ya ũremi; athamia kanua gaku na ũrĩe kĩrĩa ngũkũhe.”
Ṣùgbọ́n ìwọ, ọmọ ènìyàn, gbọ́ ohun tí mo ń sọ fún ọ. Má ṣe ṣọ̀tẹ̀ bí i ti ìdílé ọlọ́tẹ̀; la ẹnu rẹ kí o sì jẹ ohun tí mo fún ọ.”
9 Ngĩcooka ngĩcũthĩrĩria, ngĩona ndaambũrũkĩirio guoko. Guoko kũu kwanyiitĩte ibuku rĩa gĩkũnjo,
Mo sì wò, mo sì rí ọwọ́ kan tí a nà sí mi. Ìwé kíká sì wà níbẹ̀,
10 nake akĩrĩkũnjũrĩra hau mbere yakwa. Narĩo rĩandĩkĩtwo ciugo cia macakaya mĩena yeerĩ, na cia kĩrĩro, o na cia kĩeha.
ó sì tú ìwé náà fún mi. Ní ojú àti ẹ̀yìn ìwé náà ni a kọ ìpohùnréré ẹkún, ọ̀fọ̀ àti ègún sí.

< Ezekieli 2 >