< Kohelethu 1 >
1 Ici nĩcio ciugo cia Mũrutani, mũrũ wa Daudi, ũrĩa warĩ mũthamaki kũu Jerusalemu:
Ọ̀rọ̀ Oniwaasu, ọmọ Dafidi, ọba Jerusalẹmu:
2 “Maũndũ mothe nĩ ma tũhũ! Ĩĩ nĩ ma tũhũ!” Ũguo nĩguo Mũrutani ekuuga. “Ti-itherũ nĩ ma tũhũ mũtheri! Maũndũ mothe nĩ ma tũhũ.”
“Asán inú asán!” Oníwàásù náà wí pé, “Asán inú asán! Gbogbo rẹ̀ asán ni.”
3 Mũndũ-rĩ, nĩ uumithio ũrĩkũ onaga harĩ wĩra ũrĩa wothe arutaga gũkũ thĩ kwaraga riũa?
Kí ni ènìyàn rí jẹ ní èrè lórí gbogbo iṣẹ́ rẹ̀, lórí èyí tí ó ń ṣe wàhálà sí lábẹ́ oòrùn?
4 Rũciaro rũmwe rwathira-rĩ, nĩ rũngĩ rũũkaga, no rĩrĩ, thĩ ĩtũũraga o ho nginya tene na tene.
Bí ìran kan ti wá ni ìran mìíràn ń kọjá lọ, síbẹ̀ ayé dúró títí láé.
5 Riũa rĩrathaga na rĩgathũa, ningĩ rĩgacooka na ihenya kũrĩa rĩrathagĩra.
Oòrùn ń ràn, oòrùn sì ń wọ̀, ó sì sáré padà sí ibi tí ó ti yọ.
6 Rũhuho rũhurutanaga rwerekeire mwena wa gũthini, na rũgacooka rũkeerekera mwena wa gathigathini; rũthiiaga o rũgĩthiũrũrũkaga rũtegũtigithĩria, o rũgĩcookaga njĩra-inĩ yaruo.
Afẹ́fẹ́ ń fẹ́ lọ sí ìhà gúúsù, Ó sì ń fẹ́ yípo sí ìhà àríwá, a sì tún padà sí ọ̀nà rẹ̀.
7 Njũũĩ ciothe ciĩitagĩrĩra iria-inĩ, no rĩrĩ, iria rĩtirĩ hĩndĩ rĩiyũraga. O kũu njũũĩ ciumaga, nokuo icookaga.
Gbogbo odò ń sàn sí inú Òkun, síbẹ̀síbẹ̀ Òkun kò kún. Níbi tí àwọn odò ti wá, níbẹ̀ ni wọ́n tún padà sí.
8 Maũndũ mothe marehanagĩra mĩnoga ĩrĩa ĩtangĩgweteka. Riitho rĩtirĩ hĩndĩ rĩiganagia kuona, o na kana gũtũ gũkaigania kũigua.
Ohun gbogbo ni ó ń mú àárẹ̀ wá, ju èyí tí ẹnu le è sọ. Ojú kò tí ì rí ìrírí tí ó tẹ́ ẹ lọ́rùn, bẹ́ẹ̀ ni, etí kò tí ì kún fún gbígbọ́.
9 Maũndũ marĩa maanakorwo kuo no mo macookaga gũkorwo kuo rĩngĩ, naguo ũndũ ũrĩa waneekwo noguo ũcookaga ũgeekwo rĩngĩ; gũtirĩ ũndũ ũtarĩ woneka gũkũ thĩ kwaraga riũa.
Ohun tí ó ti wà tẹ́lẹ̀ náà ni yóò sì máa wà, ohun tí a ti ṣe sẹ́yìn òun ni a ó tún máa ṣe padà kò sí ohun tuntun lábẹ́ oòrùn.
10 Hihi nĩ harĩ ũndũ mũndũ angiuga atĩrĩ: “Ta rora! Ũyũ nĩ ũndũ ũtarĩ wonekana”? Ũndũ ũcio warĩ kuo hĩndĩ ndaaya hĩtũku; warĩ kuo tũtarĩ twaciarwo.
Ǹjẹ́ ohun kan wà tí ẹnìkan le è sọ wí pé, “Wò ó! Ohun tuntun ni èyí”? Ó ti wà tẹ́lẹ̀ rí ní ọjọ́ tó ti pẹ́, o ti wà ṣáájú tiwa.
11 Andũ arĩa maarĩ kuo tene matiririkanagwo, na o na arĩa matarĩ maraciarwo matikaaririkanwo nĩ arĩa magaaciarwo thuutha wao.
Kò sí ìrántí ohun ìṣáájú bẹ́ẹ̀ ni ìrántí kì yóò sí fún ohun ìkẹyìn tí ń bọ̀ lọ́dọ̀ àwọn tí ń bọ̀ ní ìgbà ìkẹyìn.
12 Niĩ Mũrutani-rĩ, ndaarĩ mũthamaki wathamakagĩra Isiraeli kũu Jerusalemu.
Èmi, Oniwaasu ti jẹ ọba lórí Israẹli ní Jerusalẹmu rí.
13 Nĩnderutĩire na kĩyo kwĩruta, na gũtuĩria na ũũgĩ maũndũ mothe marĩa mekagwo gũkũ thĩ. Kaĩ Ngai nĩakuuithĩtie andũ mũrigo mũritũ-ĩ!
Mo fi àsìkò mi sílẹ̀ láti kọ́ àti láti ṣe àwárí pẹ̀lú ọgbọ́n, gbogbo ohun tí ó ń ṣẹlẹ̀ lábẹ́ ọ̀run. Háà! Ẹrù wúwo tí Ọlọ́run ti gbé lé àwọn ènìyàn.
14 Nĩndĩĩoneire maũndũ marĩa mothe mekagwo gũkũ thĩ kwaraga riũa; maũndũ mothe no ma tũhũ, na ũguo no ta gũtengʼeria rũhuho.
Èmi ti rí ohun gbogbo tí ó ń ṣẹlẹ̀ lábẹ́ oòrùn, gbogbo rẹ̀ kò ní ìtumọ̀ bí ẹní gbìyànjú àti mú afẹ́fẹ́ ni.
15 Kĩndũ kĩrĩa kĩogomu gĩtingĩrũngĩka; nakĩo kĩrĩa gĩtarĩ ho gĩtingĩtarwo.
Ohun tí ó ti wọ́ kò le è ṣe é tọ́ mọ́, ohun tí kò sí kò le è ṣe é kà.
16 Na niĩ ngĩĩciiria, ngiuga na ngoro yakwa atĩrĩ, “Ndĩ mũkũrũ na ngagĩa na ũũgĩ mũingĩ gũkĩra andũ arĩa othe manaathana Jerusalemu mbere yakwa; nĩmenyete maũndũ maingĩ makoniĩ ũũgĩ na ũmenyo.”
Mo rò nínú ara mi, “Wò ó, mo ti dàgbà, ọgbọ́n mi sì ti pọ̀ ju ti ẹnikẹ́ni tí ó ti ṣe alákòóso Jerusalẹmu síwájú mi lọ, mo ti ní ìrírí púpọ̀ nípa ọgbọ́n àti ìmọ̀.”
17 Ningĩ nĩnderutire na ngoro yakwa kũmenya ũhoro wa ũũgĩ, o na kũmenya ũhoro wa ũgũrũki na wa ũrimũ, no ngĩmenya atĩ ũhoro ũcio, o naguo, no ta gũtengʼeria rũhuho.
Nígbà náà ni mo fi ara jì láti ní ìmọ̀ nípa ọgbọ́n, àti pàápàá àìgbọ́n àti òmùgọ̀, ṣùgbọ́n mo rí, wí pé èyí pẹ̀lú bí ẹni ń gbìyànjú àti mú afẹ́fẹ́ ni.
18 Nĩgũkorwo o ũrĩa ũũgĩ waingĩha, noguo ihooru rĩingĩhĩte; na ũrĩa ũmenyo waingĩha, noguo kĩeha kĩingĩhĩte.
Nítorí pé ọgbọ́n púpọ̀ ìbànújẹ́ púpọ̀ ní ń mú wá, bí ìmọ̀ bá sì ṣe pọ̀ tó náà ni ìbànújẹ́ ń pọ̀ tó.