< Danieli 10 >
1 Atĩrĩrĩ, mwaka-inĩ wa ĩtatũ wa Kurusu mũthamaki wa Perisia, Danieli (na nĩwe watuĩtwo Beliteshazaru) nĩaguũrĩirio maũndũ. Ndũmĩrĩri ya ũguũrio ũcio yarĩ ya ma, na yakoniĩ ũhoro wa mbaara nene. Gũtaũkĩrwo kwa ndũmĩrĩri ĩyo guokire kũrĩ we na njĩra ya kĩoneki.
Ní ọdún kẹta Kirusi ọba Persia, a fi ìran kan hàn Daniẹli (ẹni tí à ń pè ní Belteṣassari). Òtítọ́ ni ọ̀rọ̀ ìran náà, ó sì ní í ṣe pẹ̀lú àsìkò ìpọ́njú ńlá, òye ọ̀rọ̀ náà wá bá a nínú ìran.
2 Ihinda-inĩ rĩu-rĩ, niĩ Danieli ndaakoretwo ngĩcakaya handũ ha ciumia ithatũ.
Ní àsìkò náà, èmi Daniẹli ṣọ̀fọ̀ fún ọ̀sẹ̀ mẹ́ta.
3 Nĩndehingĩte kũrĩa irio njega; kanua gakwa gatiacamire nyama kana ndibei; ningĩ ndiehakaga maguta o na hanini, o nginya ciumia icio ithatũ igĩthira.
Èmi kì í jẹ oúnjẹ tí ó dára, èmi kò fi ẹran tàbí wáìnì kan ẹnu mi, bẹ́ẹ̀ ni èmi kò fi òróró para títí ọ̀sẹ̀ mẹ́ta fi kọjá.
4 Mũthenya wa mĩrongo ĩĩrĩ na ĩna wa mweri wa mbere, ndũgamĩte hũgũrũrũ-inĩ cia, rũũĩ rũrĩa rũnene rwa Tigirisi,
Ní ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù àkọ́kọ́, bí mo ti dúró sí etí i bèbè odò ńlá Tigirisi,
5 ngĩtiira maitho, na hau mbere yakwa ngĩona mũndũ wehumbĩte nguo cia gatani, na akehotora mũcibi wa thahabu ĩrĩa therie mũno.
mo wo òkè, mo rí ọkùnrin kan tí ó wọ aṣọ àlà, ẹ̀gbẹ́ ẹni tí a fi wúrà Upasi dáradára dì ní àmùrè.
6 Mwĩrĩ wake watariĩ ta inagĩ rĩrĩa rĩĩtagwo thumarati, na ũthiũ wake wahenagia ta rũheni, maitho make maahaanaga ta imũrĩ cia mwaki, na moko make na magũrũ maahaanaga ta gĩcango gĩkumuthe gĩkahenia, naguo mũgambo wake watariĩ ta mũgambo wa andũ aingĩ.
Ara rẹ̀ dàbí berili, ojú u rẹ̀ dàbí mọ̀nàmọ́ná, ẹyin ojú u rẹ̀ dàbí iná àtẹ̀tàn, apá àti ẹsẹ̀ rẹ̀ dàbí ìtànná ìmọ́lẹ̀ tí o kún fún idẹ, àti ohùn rẹ̀ dàbí i ti ìjọ ènìyàn púpọ̀.
7 Niĩ Danieli-rĩ, no niĩ nyiki ndonire kĩoneki kĩu; nĩgũkorwo andũ arĩa twarĩ nao matiakĩonire, no nĩmaiyũrirwo nĩ guoya, makĩũra magĩthiĩ kwĩhitha.
Èmi Daniẹli, ni ẹnìkan tí ó rí ìran náà, àwọn ọkùnrin tí ó wà pẹ̀lú u mi, wọn kò rí i, ṣùgbọ́n ìpayà ńlá dà bò wọ́n, wọ́n sálọ wọ́n sì fi ara pamọ́.
8 Nĩ ũndũ ũcio ngĩtigwo ndĩ o nyiki ndĩĩroreire kĩoneki kĩu kĩnene. Ngĩcooka ngĩthirwo nĩ hinya, ngĩthitia gĩthiithi ta ngũkua, na gũtirĩ ũndũ ingĩahotire gwĩka.
Ó sì ku èmi nìkan, tí mo rí ìran ńlá yìí, kò sì ku okun kankan fún mi, ojú u mi sì rẹ̀wẹ̀sì gidigidi, n kò sì ní agbára mọ́.
9 Ngĩcooka ngĩigua akĩaria, na rĩrĩa ndamũthikagĩrĩria, ngĩnyiitwo nĩ toro mũnene, ngĩgwa ndurumithĩtie ũthiũ wakwa thĩ.
Nígbà náà, ni mo gbọ́ tí ó ń sọ̀rọ̀, bí mo ṣe tẹ́tí sílẹ̀ sí i, mo sùn lọ fọnfọn, ní ìdojúbolẹ̀.
10 Na rĩrĩ, ngĩhutio na guoko, gũkĩnjoya na igũrũ, gũkĩnjiga ndũrĩtie ndu ndĩnyiitĩrĩire thĩ na moko, ngĩinainaga.
Ọwọ́ kan kàn mí, ó gbé mi dìde ní ìwárìrì lórí ọwọ́ àti eékún mi.
11 Nake akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Danieli, wee mũtĩĩe mũno, cũrania wega ciugo ici ngirie gũkwarĩria, na ũũkĩre na igũrũ, nĩgũkorwo rĩu nĩgũtũmwo ndatũmwo kũrĩ we.” Na aarĩkia kũnjĩĩra ũguo, ngĩrũgama o ngĩinainaga.
Ó sọ pé, “Daniẹli ẹni tí a yàn fẹ́ gidigidi gba ọ̀rọ̀ tí mo fẹ́ bá ọ sọ yìí yẹ̀ wò dáradára, kí o sì dìde, nítorí tí a rán mi sí ọ.” Bí ó ṣe sọ èyí fún mi, mo dìde ní ìwárìrì.
12 Agĩcooka agĩthiĩ na mbere akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Danieli, tiga gwĩtigĩra. Kuuma mũthenya wa mbere rĩrĩa wambĩrĩirie gũtuĩria ũhoro ũyũ na ũkĩĩnyiihia mbere ya Ngai waku-rĩ, ciugo ciaku nĩciaiguirwo, na rĩu ndoka nĩgeetha ngũhe ũhoro wacio.
Nígbà náà ni ó tẹ̀síwájú, pé, “Má ṣe bẹ̀rù Daniẹli. Láti ọjọ́ àkọ́kọ́ tí ìwọ ti fi ọkàn rẹ sílẹ̀ níwájú Ọlọ́run rẹ, a gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ, mo sì wá nítorí ọ̀rọ̀ náà.
13 No rĩrĩ, mũnene wa ũthamaki wa Perisia nĩangirĩrĩirie mĩthenya mĩrongo ĩĩrĩ na ũmwe. Hĩndĩ ĩyo nĩrĩo Mikaeli, ũmwe wa araika arĩa anene, okire kũndeithia, tondũ nĩndahingĩrĩirio kũu hamwe na mũthamaki wa Perisia.
Ṣùgbọ́n ọmọ-aládé ìjọba Persia dá mi dúró fún ọjọ́ mọ́kànlélógún. Nígbà náà ni Mikaeli, ọ̀kan lára ìjòyè àwọn ọmọ-aládé, wá láti ràn mi lọ́wọ́, nítorí a dá mi dúró níbẹ̀ pẹ̀lú ọba Persia.
14 Rĩu ndoka ngũtaarĩrie maũndũ marĩa magaakora andũ anyu matukũ ma thuutha, tondũ kĩoneki kĩu gĩkoniĩ ihinda rĩrĩa rĩgooka.”
Ní ìsinsin yìí mo wá láti ṣàlàyé ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ sí àwọn ènìyàn rẹ ní ọjọ́ iwájú, nítorí ìran náà ń sọ nípa ọjọ́ iwájú.”
15 Na rĩrĩa aanjĩĩraga ũhoro ũcio, ngĩinamia ũthiũ thĩ, ngĩremwo nĩ kwaria.
Bí ó sì ti ń sọ nǹkan wọ̀nyí fún mi, mo sì dorí kodò mo sì dákẹ́.
16 Ningĩ ũngĩ wahaanaga ta mũndũ akĩhutia iromo ciakwa, ngĩtumũra kanua na ngĩambĩrĩria kwaria. Ngĩĩra ũcio warũngiĩ mbere yakwa atĩrĩ, “Mwathi wakwa, niĩ ndĩmũhoote nĩ ruo rũnene tondũ wa kĩoneki kĩu, na ndirĩ na ũndũ ingĩhota gwĩka.
Nígbà náà, ni ẹnìkan tí ó rí bí ènìyàn fi ọwọ́ kan ètè mi, mo la ẹnu mi, mo sì bẹ̀rẹ̀ sí ní sọ ọ̀rọ̀, mo sọ fún ẹni tí ó dúró níwájú mi, “Ìrònú sì mú mi, nítorí ìran náà, olúwa mi, n kò sì ní okun.
17 Niĩ ndungata yaku-rĩ, ndaakĩhota atĩa kwaria nawe mwathi wakwa? Nĩgũkorwo nĩthirĩtwo nĩ hinya o na mĩhũmũ yakwa.”
Ǹjẹ́ báwo ni èmi ìránṣẹ́ ẹ̀ rẹ ṣe lè bá ọ sọ̀rọ̀, olúwa mi? Agbára mi ti lọ, agbára káká ni mo fi ń mí.”
18 Ningĩ ngĩcooka ngĩigua ndaahutio rĩngĩ nĩ ũcio wahaanaga ta mũndũ, akĩnjĩkĩra hinya.
Ẹ̀wẹ̀, ẹnìkan tí ó rí bí ènìyàn fi ọwọ́ kàn mí, ó sì fún mi ní agbára.
19 Akĩnjĩĩra atĩrĩ, “Tiga gwĩtigĩra, wee mũndũ ũyũ mũtĩĩe mũno, ũrogĩa na thayũ! Wĩyũmĩrĩrie; wĩĩkĩre hinya.” Na rĩrĩa aanjarĩirie ũguo, ngĩcookwo nĩ hinya, na niĩ ngiuga atĩrĩ, “Rĩu mwathi wakwa aria tondũ nĩwanjĩkĩra hinya.”
Ó sì wí pé, “Má ṣe bẹ̀rù, ìwọ ọkùnrin olùfẹ́ gidigidi. Àlàáfíà ni fún ọ, mú ara le, àní mú ara le.” Nígbà tí ohun bá mi sọ̀rọ̀, a sì mú mi lára le. “Mo sì wí pé, kí olúwa mi kí ó máa sọ̀rọ̀, níwọ̀n ìgbà tí ìwọ ti mú mi ní ara le.”
20 Nake akĩnjũũria atĩrĩ, “Wee nĩũũĩ kĩrĩa gĩtũmĩte njũke kũrĩ we? Nĩngũcooka o narua ngarũe na mũnene wa Perisia, na ndathiĩ-rĩ, nake mũnene wa Ũyunani nĩegũka;
Nígbà náà, ni ó wí pé, “Ṣé o mọ ìdí tí mo fi tọ̀ ọ́ wá? Láìpẹ́ èmi yóò yípadà lọ bá àwọn ọmọ-aládé Persia jà, nígbà tí mo bá lọ àwọn ọmọ-aládé Giriki yóò wá;
21 no nĩngwamba gũkwĩra ũrĩa kwandĩkĩtwo Ibuku-inĩ-rĩa-Ma. (Ndirĩ mũndũ ũndeithagia ngĩrũa nao tiga Mikaeli, mũnene wanyu.
ṣùgbọ́n ní àkọ́kọ́, èmi yóò sọ ohun tí wọ́n kọ sínú ìwé òtítọ́ fún ọ. (Kò sí ẹni tí ó kún mi lọ́wọ́ fún nǹkan wọ̀nyí bí kò ṣe Mikaeli, ọmọ-aládé e yín.