< 2 Samũeli 9 >

1 Nake Daudi akĩũria atĩrĩ, “Nĩ kũrĩ mũndũ o na ũmwe ũtigarĩte wa nyũmba ya Saũlũ ũrĩa ingĩtuga nĩ ũndũ wa Jonathani?”
Dafidi sì béèrè pé, ọ̀kan nínú àwọn ẹni tí ń ṣe ìdílé Saulu kù síbẹ̀ bí? Kí èmi lè ṣe oore fún un nítorí Jonatani.
2 Na rĩrĩ, nĩ kwarĩ na ndungata ya mũciĩ wa Saũlũ yetagwo Ziba. Nao makĩmĩĩta ĩthiĩ mbere ya Daudi, nake mũthamaki akĩmĩũria atĩrĩ, “Wee nĩwe Ziba?” Nayo ĩgĩcookia atĩrĩ, “Ĩĩ nĩ niĩ ndungata yaku.”
Ìránṣẹ́ kan sì ti wà ní ìdílé Saulu, orúkọ rẹ̀ sí ń jẹ́ Ṣiba, wọ́n sì pè é wá sọ́dọ̀ Dafidi, ọba sì béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Ìwọ ni Ṣiba bí?” Ó sì dáhùn wí pé, “Ìránṣẹ́ rẹ ni.”
3 Nake mũthamaki akĩũria atĩrĩ, “Gũtirĩ mũndũ o na ũmwe ũtigarĩte wa nyũmba ya Saũlũ ũrĩa ingĩonia ũtugi wa Ngai?” Nake Ziba agĩcookeria mũthamaki atĩrĩ, “Nĩ kũrĩ na mũrũ wa Jonathani; nake nĩ mwonju magũrũ meerĩ.”
Ọba sì wí pé, “Kò ha sí ọ̀kan nínú ìdílé Saulu síbẹ̀, kí èmi ṣe oore Ọlọ́run fún un?” Ṣiba sì wí fún ọba pé, “Jonatani ní ọmọ kan síbẹ̀ tó ya arọ.”
4 Nake mũthamaki akĩũria atĩrĩ, “Arĩ ha?” Ziba akĩmũcookeria atĩrĩ, “Arĩ mũciĩ kwa Makiru mũrũ wa Amieli kũu Lo-Debari.”
Ọba sì wí fún un pé, “Níbo ni ó gbé wà?” Ṣiba sì wí fún ọba pé, “Wò ó, òun wà ní ilé Makiri, ọmọ Ammieli, ní Lo-Debari.”
5 Nĩ ũndũ ũcio, Mũthamaki Daudi agĩtũmana areehwo kuuma nyũmba ya Makiru mũrũ wa Amieli, kũu Lo-Debari.
Dafidi ọba sì ránṣẹ́, ó sì mú un láti ilé Makiri ọmọ Ammieli láti Lo-Debari wá.
6 Rĩrĩa Mefiboshethu mũrũ wa Jonathani, mũrũ wa Saũlũ, ookire harĩ Daudi, akĩinamĩrĩra amũhe gĩtĩĩo. Nake Daudi akĩmwĩta “Mefiboshethu!” Nake agĩcookia atĩrĩ, “Niĩ ũyũ ndungata yaku.”
Mefiboṣeti ọmọ Jonatani ọmọ Saulu sì tọ Dafidi wá, ó sì wólẹ̀ níwájú rẹ̀, ó sì bú ọlá fún un. Dafidi sì wí pé, “Mefiboṣeti!” Òun sì dáhùn wí pé, “Wò ó, ìránṣẹ́ rẹ!”
7 Nake Daudi akĩmwĩra atĩrĩ, “Tiga gwĩtigĩra, nĩgũkorwo ti-itherũ nĩngũgũtuga nĩ ũndũ wa thoguo Jonathani. Nĩngũgũcookeria gĩthaka gĩothe kĩrĩa kĩarĩ gĩa gukaguo Saũlũ, nawe ũrĩrĩĩagĩra irio metha-inĩ yakwa hĩndĩ ciothe.”
Dafidi sì wí fún un pé, “Má ṣe bẹ̀rù, nítorí pé nítòótọ́ èmi ó ṣe oore fún ọ nítorí Jonatani baba rẹ, èmi ó sì tún fi gbogbo ilé Saulu baba rẹ fún ọ, ìwọ ó sì máa bá mi jẹun nígbà gbogbo ní ibi oúnjẹ mi.”
8 Nake Mefiboshethu akĩinamĩrĩra, akiuga atĩrĩ, “Ndungata yaku ĩkĩrĩ kĩ, atĩ nĩguo ũrũmbũiye ngui nguũ ta niĩ?”
Mefiboṣeti sì tẹríba, ó sì wí pé, “Kí ni ìránṣẹ́ rẹ jásí, tí ìwọ ó fi máa wo òkú ajá bí èmi.”
9 Hĩndĩ ĩyo mũthamaki agĩtũmanĩra Ziba, ndungata ya Saũlũ, akĩmwĩra atĩrĩ, “Nĩndahe mũrũ wa mũriũ wa mwathi waku indo ciothe iria ciarĩ cia Saũlũ na cia nyũmba yake.
Ọba sì pe Ṣiba ìránṣẹ́ Saulu, ó sì wí fún un pé, “Gbogbo nǹkan tí í ṣe ti Saulu, àti gbogbo èyí tí í ṣe ti ìdílé rẹ̀ ni èmi fi fún ọmọ olúwa rẹ.
10 Wee, hamwe na ariũ aku na ndungata ciaku, nĩ inyuĩ mũrĩmũrĩmagĩra mũgũnda, na mũkainũkia magetha, nĩgeetha mũrũ wa mũriũ wa mwathi waku oonage irio. Nake Mefiboshethu, mũrũ wa mũriũ wa mwathi waku, arĩrĩĩagĩra irio metha-inĩ yakwa hĩndĩ ciothe.” (Na rĩrĩ, Ziba aarĩ na ariũ ikũmi na atano, na ndungata mĩrongo ĩĩrĩ.)
Ìwọ, àti àwọn ọmọ rẹ, àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ ni yóò sì máa ro ilẹ̀ náà fún un, ìwọ ni yóò sì máa mú ìkórè wá, ọmọ olúwa rẹ yóò sì máa rí oúnjẹ jẹ, ṣùgbọ́n Mefiboṣeti ọmọ olúwa rẹ yóò sì máa bá mi jẹun nígbà gbogbo ní ibi oúnjẹ mi.” (Ṣiba sì ní ọmọ mẹ́ẹ̀ẹ́dógún àti ogún ìránṣẹ́kùnrin.)
11 Ningĩ Ziba akĩĩra mũthamaki atĩrĩ, “Ndungata yaku nĩĩgwĩka o ũrĩa wothe mũthamaki, mwathi wakwa, egwatha ndungata yake ĩĩke.” Nĩ ũndũ ũcio Mefiboshethu aarĩĩagĩra irio metha-inĩ ya Daudi taarĩ ũmwe wa ariũ a mũthamaki.
Ṣiba sì wí fún ọba pé, “Gẹ́gẹ́ bí gbogbo èyí tí olúwa mi ọba ti pàṣẹ fún ìránṣẹ́ rẹ, bẹ́ẹ̀ náà ni ìránṣẹ́ rẹ ó ṣe.” Ọba sì wí pé, “Ní ti Mefiboṣeti, yóò máa jẹun ní ibi oúnjẹ mi, gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan nínú àwọn ọmọ ọba.”
12 Mefiboshethu aarĩ na kamwana geetagwo Mika, nao andũ othe a mũciĩ wa Ziba maarĩ ndungata cia Mefiboshethu.
Mefiboṣeti sì ní ọmọ kékeré kan, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Mika. Gbogbo àwọn tí ń gbé ní ilé Ṣiba ni ó sì ń ṣe ìránṣẹ́ fún Mefiboṣeti.
13 Nake Mefiboshethu agĩtũũra Jerusalemu, tondũ aarĩĩagĩra irio metha-inĩ ya mũthamaki hĩndĩ ciothe, nake arĩ mwonju magũrũ meerĩ.
Mefiboṣeti sì ń gbé ní Jerusalẹmu, òun a sì máa jẹun nígbà gbogbo ní ibi oúnjẹ ọba; òun sì yarọ ní ẹsẹ̀ rẹ̀ méjèèjì.

< 2 Samũeli 9 >