< 2 Samũeli 21 >
1 Na rĩrĩ, hĩndĩ ya wathani wa Daudi, nĩ kwagĩire na ngʼaragu ya mĩaka ĩtatũ ĩrũmanĩrĩire; nĩ ũndũ ũcio Daudi agĩtuĩria ũhoro harĩ Jehova. Nake Jehova akiuga atĩrĩ, “Ũndũ ũyũ ũrekĩka nĩ ũndũ wa Saũlũ o na ũndũ wa nyũmba yake ĩrĩa yaitithagia thakame; nĩ ũndũ wa ũrĩa ooragire andũ a Gibeoni.”
Ìyàn kan sì mú lọ́jọ́ Dafidi ní ọdún mẹ́ta, láti ọdún dé ọdún; Dafidi sì béèrè lọ́dọ̀ Olúwa, Olúwa sì wí pé, “Nítorí ti Saulu ni, àti nítorí ilé rẹ̀ tí ó kún fún ẹ̀jẹ̀, nítorí pé ó pa àwọn ará Gibeoni.”
2 Nake mũthamaki agĩĩta andũ a Gibeoni akĩaria nao. (Na rĩrĩ, andũ acio a Gibeoni matiarĩ amwe na Isiraeli no maarĩ matigari ma Aamori; no andũ a Isiraeli nĩmehĩtĩte atĩ matikamooraga, no Saũlũ nĩ ũndũ wa kĩyo kĩrĩa aarĩ nakĩo nĩ ũndũ wa Isiraeli na Juda nĩageririe kũmaniina.)
Ọba sì pe àwọn ará Gibeoni, ó sì bá wọn sọ̀rọ̀; àwọn ará Gibeoni kì í ṣe ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Israẹli, ṣùgbọ́n wọ́n jẹ́ àwọn tí ó kù nínú àwọn ọmọ Amori; àwọn ọmọ Israẹli sì ti búra fún wọn, Saulu sì ń wá ọ̀nà àti pa wọ́n ní ìtara rẹ̀ fún àwọn ọmọ Israẹli àti Juda.
3 Nake Daudi akĩũria andũ acio a Gibeoni atĩrĩ, “Mũngĩenda ndĩmwĩkĩre atĩa? Nĩ ũndũ ũrĩkũ ingĩĩka tũiguane nĩguo mũrathime igai rĩa Jehova?”
Dafidi sì bi àwọn ará Gibeoni léèrè pé, “Kí ni èmi ó ṣe fún un yín? Àti kín ni èmi ó fi ṣe ètùtù, kí ẹ̀yin lè súre fún ilẹ̀ ìní Olúwa?”
4 Nao andũ a Gibeoni makĩmũcookeria atĩrĩ, “Tũtiagĩrĩirwo nĩ kũũria tũheo betha kana thahabu kuuma kũrĩ Saũlũ, kana nyũmba yake, o na tũtirĩ na kĩhooto gĩa kũũraga mũndũ o na ũmwe thĩinĩ wa Isiraeli.” Daudi akĩmooria atĩrĩ, “Nĩatĩa mũngĩenda ndĩmwĩkĩre?”
Àwọn ará Gibeoni sì wí fún un pé, “Kì í ṣe ọ̀rọ̀ fàdákà tàbí wúrà láàrín wa àti Saulu tàbí ìdílé rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni a kò sì fẹ́ kí ẹ pa ẹnìkan ní Israẹli.” Dafidi sì wí pé, “Èyí tí ẹ̀yin bá wí ni èmi ó ṣe?”
5 Nao magĩcookeria mũthamaki atĩrĩ, “Ha ũhoro wa mũndũ ũrĩa watũniinire na agĩtũciirĩra ũũru nĩgeetha tũthire, nĩguo tũtikagĩe na handũ o na ha thĩinĩ wa Isiraeli-rĩ,
Wọ́n sì wí fún ọba pé, “Ọkùnrin tí ó run wá, tí ó sì rò láti pa wá rẹ́ ki a má kù níbikíbi nínú gbogbo agbègbè Israẹli.
6 reke tũneo arũme mũgwanja a njiaro ciake nĩgeetha mooragwo na maraganio mbere ya Jehova kũu Gibea ya Saũlũ, ũrĩa mũthuure wa Jehova.” Nĩ ũndũ ũcio mũthamaki akiuga atĩrĩ, “Nĩngũmaneana kũrĩ inyuĩ.”
Mú ọkùnrin méje nínú àwọn ọmọ rẹ̀ fún wá, àwa ó sì so wọ́n rọ̀ fún Olúwa ní Gibeah ti Saulu ẹni tí Olúwa ti yàn.” Ọba sì wí pé, “Èmi ó fi wọ́n fún yín.”
7 Na rĩrĩ, mũthamaki akĩhonokia Mefiboshethu mũrũ wa Jonathani, mũrũ wa Saũlũ, nĩ ũndũ wa mwĩhĩtwa ũrĩa Daudi na Jonathani mũrũ wa Saũlũ meehĩtanĩire mbere ya Jehova.
Ṣùgbọ́n ọba dá Mefiboṣeti sí, ọmọ Jonatani, ọmọ Saulu, nítorí ìbúra Olúwa tí ó wà láàrín Dafidi àti Jonatani ọmọ Saulu.
8 No mũthamaki agĩkuua Arimoni na Mefiboshethu, ariũ acio eerĩ a Aia, mwarĩ wa Rizipa, arĩa aaciarĩire Saũlũ, hamwe na ariũ atano a Merabu mwarĩ wa Saũlũ, arĩa aaciarĩire Adirieli mũrũ wa Barizilai ũrĩa Mũmeholathu;
Ọba sì mú àwọn ọmọkùnrin méjèèjì tí Rispa ọmọbìnrin Aiah bí fún Saulu, àní Ammoni àti Mefiboṣeti àwọn ọmọkùnrin márààrún ti Merabu, ọmọbìnrin Saulu, àwọn tí ó bí fún Adrieli ọmọ Barsillai ará Mehola.
9 Nake akĩmaneana kũrĩ Gibeoni, arĩa maamooragire na makĩmaaragania kĩrĩma-inĩ mbere ya Jehova. Acio othe mũgwanja maagũire hamwe; mooragirwo hĩndĩ ya matukũ ma kĩambĩrĩria kĩa magetha, o rĩrĩa magetha ma cairi maambagĩrĩria.
Ó sì fi wọ́n lé àwọn ará Gibeah lọ́wọ́, wọ́n sì so wọ́n rọ̀ lórí òkè níwájú Olúwa: àwọn méjèèjì sì ṣubú lẹ́ẹ̀kan, a sì pa wọ́n ní ìgbà ìkórè, ní ìbẹ̀rẹ̀, ìkórè ọkà barle.
10 Rizipa mwarĩ wa Aia akĩoya nguo ya ikũnia, na akĩmĩara hau ihiga igũrũ. Kuuma kĩambĩrĩria kĩa magetha nginya rĩrĩa mbura yoirĩire mĩĩrĩ ĩyo, ndaarekire ciimba icio ihutio nĩ nyoni cia rĩera-inĩ mũthenya, kana ihutio nĩ nyamũ cia gĩthaka ũtukũ.
Rispa ọmọbìnrin Aiah sì mú aṣọ ọ̀fọ̀ kan, ó sì tẹ́ fún ará rẹ̀ lórí àpáta ní ìbẹ̀rẹ̀ ìkórè, títí omi fi dà sí wọn lára láti ọ̀run wá, kò sì jẹ́ kí àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run bà lé wọn lọ́sàn, tàbí àwọn ẹranko igbó lóru.
11 Hĩndĩ ĩrĩa Daudi eerirwo ũrĩa Rizipa mwarĩ wa Aia, thuriya ya Saũlũ, eekĩte-rĩ,
A sì ro èyí, tí Rispa ọmọbìnrin Aiah obìnrin Saulu ṣe, fún Dafidi.
12 agĩthiĩ, agĩkuua mahĩndĩ ma Saũlũ o na ma mũriũ Jonathani kuuma kwa andũ a Jabeshi-Gileadi. Maamarutĩte na hitho kuuma kĩhaaro-inĩ kĩa mũingĩ kũu Bethi-Shani, harĩa Afilisti maamacuurĩtie, thuutha wa kũũragĩra Saũlũ kũu Giliboa.
Dafidi sì lọ ó sì kó egungun Saulu, àti egungun Jonatani ọmọ rẹ̀ kúrò lọ́dọ̀ àwọn ọkùnrin Jabesi Gileadi, àwọn tí ó jí wọn kúrò ní ìta Beti-Ṣani, níbi tí àwọn Filistini gbé so wọ́n rọ̀, nígbà tí àwọn Filistini pa Saulu ní Gilboa.
13 Daudi agĩkuua mahĩndĩ ma Saũlũ na ma mũriũ Jonathani kuuma kũu, na mahĩndĩ ma andũ arĩa moragĩtwo makaaraganio kũu makĩũnganio.
Ó sì mú egungun Saulu àti egungun Jonatani ọmọ rẹ̀ láti ibẹ̀ náà wá; wọ́n sì kó egungun àwọn tí a ti so rọ̀ jọ.
14 Nao magĩthika mahĩndĩ ma Saũlũ na ma mũriũ Jonathani mbĩrĩra-inĩ ya Kishu, ithe wa Saũlũ, kũu Zela thĩinĩ wa Benjamini, na magĩĩka maũndũ mothe marĩa mũthamaki aathanĩte. Thuutha ũcio Ngai agĩcookia mahooya marĩa maahooetwo nĩ ũndũ wa bũrũri.
Wọ́n sì sin egungun Saulu àti ti Jonatani ọmọ rẹ̀ ní ilé Benjamini, ní Ṣela, nínú ibojì Kiṣi baba rẹ̀, wọ́n sì ṣe gbogbo èyí tí ọba paláṣẹ, lẹ́yìn èyí ni Ọlọ́run si gba ẹ̀bẹ̀ nítorí ilẹ̀ náà.
15 O rĩngĩ nĩ kwagĩire mbaara gatagatĩ ka Afilisti na Isiraeli. Daudi agĩikũrũka agĩthiĩ hamwe na andũ ake makarũe na Afilisti, na akĩnoga mũno.
Ogun sì tún wà láàrín àwọn Filistini àti Israẹli; Dafidi sì sọ̀kalẹ̀, àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pẹ̀lú rẹ̀, ó sì bá àwọn Filistini jà, ó sì rẹ Dafidi.
16 Nake Ishibi-Benobu ũrĩa warĩ ũmwe wa njiaro cia Rafa, ũrĩa mũthia wa itimũ rĩake warĩ na ũritũ wa cekeri magana matatũ, na aarĩ na rũhiũ rwa njora rwerũ, ũcio akiuga nĩekũũraga Daudi.
Iṣbi-Benobu sì jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn Rafa, ẹni tí ọ̀kọ̀ rẹ̀ wọn ọ̀ọ́dúnrún ṣékélì idẹ, ó sì sán idà tuntun, ó sì gbèrò láti pa Dafidi.
17 No rĩrĩ, Abishai mũrũ wa Zeruia akĩhonokia Daudi; akĩgũtha Mũfilisti ũcio akĩgũa, akĩmũũraga. Ningĩ andũ a Daudi makĩĩhĩta kũrĩ we makiuga atĩrĩ, “Gũtirĩ hĩndĩ ũgacooka gũthiĩ mbaara-inĩ na ithuĩ, nĩgeetha tawa wa Isiraeli ndũkahorio.”
Ṣùgbọ́n Abiṣai ọmọ Seruiah ràn án lọ́wọ́, ó sì kọlu Filistini náà, ó sì pa á. Nígbà náà ni àwọn ìránṣẹ́ Dafidi sì búra fún un pé, “Ìwọ kì yóò sì tún bá wa jáde lọ sí ibi ìjà mọ́ kí ìwọ má ṣe pa iná Israẹli.”
18 Ningĩ thuutha wa mahinda macio, makĩgĩa na mbaara ĩngĩ na Afilisti kũu Gobu. Hĩndĩ ĩyo Sibekai ũrĩa Mũhushathi akĩũraga Safu, ũmwe wa njiaro cia Rafa.
Lẹ́yìn èyí, ìjà kan sì tún wà láàrín àwọn Israẹli àti àwọn Filistini ní Gobu, nígbà náà ni Sibekai ará Huṣati pa Safu, ẹni tí í ṣe ọ̀kan nínú àwọn Rafa.
19 Ningĩ mbaara-inĩ ĩngĩ makĩrũa na Afilisti kũu Gobu, Elihanani mũrũ wa Jaare-Oregimu ũrĩa Mũbethilehemu akĩũraga Goliathũ ũrĩa Mũgiiti, ũrĩa warĩ na itimũ rĩarĩ na mũtĩ ũigana ta mũtĩ wa mũtumi ngoora.
Ìjà kan sì tún wà ní Gobu láàrín àwọn Israẹli àti àwọn Filistini, Elhanani ọmọ Jairi ará Bẹtilẹhẹmu sì pa arákùnrin Goliati ará Gitti, ẹni tí ọ̀pá ọ̀kọ̀ rẹ̀ dàbí ìdábùú apásá ìhunṣọ.
20 Ningĩ mbaara-inĩ ĩngĩ ĩrĩa yarĩ kũu Gathu, nakuo kwarĩ na mũndũ mũnene mũno, warĩ na ciara ithathatũ o guoko, na ciara ithathatũ o kũgũrũ, ciothe ciarĩ ciara mĩrongo ĩĩrĩ na inya. O na ningĩ aarĩ wa rũciaro rwa Rafa.
Ìjà kan sì tún wà ní Gati, ọkùnrin kan sì wà tí ó ga púpọ̀, ó sì ní ìka mẹ́fà ní ọwọ́ kan, àti ọmọ ẹsẹ̀ mẹ́fà ní ẹsẹ̀ kan, àpapọ̀ rẹ̀ sì jẹ́ mẹ́rìnlélógún; a sì bí òun náà ní Rafa.
21 Rĩrĩa aanyũrũririe andũ a Isiraeli, Jonathani mũrũ wa Shimea, mũrũ wa nyina na Daudi, akĩmũũraga.
Nígbà tí òun sì pe Israẹli ní ìjà. Jonatani ọmọ Ṣimea arákùnrin Dafidi sì pa á.
22 Andũ acio ana maarĩ a rũciaro rwa Rafa kũu Gathu nao makĩgũa moko-inĩ ma Daudi na andũ ake.
Àwọn mẹ́rẹ̀ẹ̀rin wọ̀nyí ni ìran Rafa ní Gati, wọ́n sì ti ọwọ́ Dafidi ṣubú àti ọwọ́ àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀.