< 2 Athamaki 22 >
1 Na rĩrĩ, Josia aarĩ wa mĩaka ĩnana rĩrĩa aatuĩkire mũthamaki, nake agĩthamaka arĩ Jerusalemu mĩaka mĩrongo ĩtatũ na ũmwe. Nyina eetagwo Jedida mwarĩ wa Adaia; oimĩte Bozikathu.
Josiah jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́jọ nígbà tí ó di ọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kànlélọ́gbọ̀n. Orúkọ ìyá rẹ̀ a máa jẹ́ Jedida ọmọbìnrin Adaiah; ó wá láti Boskati.
2 Nake agĩĩka ũrĩa kwagĩrĩire maitho-inĩ ma Jehova, na agĩthiĩ na mĩthiĩre yothe ya ithe Daudi atekwĩhũgũra mwena wa ũrĩo kana wa ũmotho.
Ó sì ṣe èyí tí ó dára lójú Olúwa, ó sì rìn ní ọ̀nà Dafidi baba a rẹ̀, kò sì yípadà sí apá ọ̀tún tàbí sí apá òsì.
3 Mwaka-inĩ wa ikũmi na ĩnana wa wathani wake, Mũthamaki Josia agĩtũma Shafani mũrũ wa Azalia mũrũ wa Meshulamu, ũrĩa warĩ mwandĩki-marũa, athiĩ hekarũ-inĩ ya Jehova. Akĩmwĩra atĩrĩ:
Ní ọdún kejìdínlógún tí ó fi jẹ ọba. Ọba Josiah rán akọ̀wé, Ṣafani ọmọ Asalia, ọmọ Meṣullamu, sí ilé Olúwa. Ó wí pé,
4 “Ambata, ũthiĩ kũrĩ Hilikia mũthĩnjĩri-Ngai ũrĩa mũnene na ũmwĩre ahaarĩrie mbeeca iria irehetwo hekarũ-inĩ ya Jehova, iria arangĩri a mĩrango monganĩtie kuuma kũrĩ andũ.
“Gòkè lọ sí ọ̀dọ̀ Hilkiah olórí àlùfáà, kí o sì jẹ́ kí ó ṣírò iye owó tí a mú wá sí ilé Olúwa, tí àwọn olùṣọ́nà ti gbà lọ́wọ́ àwọn ènìyàn.
5 Nao maciĩhokere andũ arĩa mathuurĩtwo a kũrũgamĩrĩra wĩra wa hekarũ. Andũ acio ũtigĩrĩre nĩ marĩha aruti a wĩra arĩa macookagĩrĩria hekarũ ya Jehova,
Ẹ sì jẹ́ kí wọn ó fi lé àwọn ọkùnrin tí a ti yàn láti bojútó iṣẹ́ náà lórí ilé Olúwa. Kí ẹ sì jẹ́ kí àwọn ọkùnrin san án fún àwọn òṣìṣẹ́ tí ó ń tún ilé Olúwa ṣe.
6 nao nĩ atharamara, na andũ a gwaka, na aaki a mahiga. Na ningĩ ũtigĩrĩre nĩmagũra mbaũ na mahiga maicũhie ma gũcookereria hekarũ.
Àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà, àwọn ọ̀mọ̀lé àti àwọn akọ́lé. Bákan náà ni wọ́n ra igi àti òkúta ọlọ́ṣọ̀ọ́ láti fi tún tẹmpili ṣe.
7 No rĩrĩ, to nginya maheane mathabu ma mbeeca iria meehokeirwo, tondũ mararuta wĩra ũcio na kwĩhokeka.”
Ṣùgbọ́n wọn kò ní láti ṣe ìṣirò fún owó náà tí a fi fún wọn, nítorí wọ́n ṣe òtítọ́.”
8 Hilikia mũthĩnjĩri-Ngai ũrĩa mũnene akĩĩra Shafani ũcio mwandĩki marũa atĩrĩ, “Nĩnyonete Ibuku rĩa Watho thĩinĩ wa hekarũ ya Jehova.” Akĩrĩnengera Shafani nake akĩrĩthoma.
Hilkiah olórí àlùfáà sọ fún Ṣafani akọ̀wé pé, “Èmi rí ìwé òfin nílé Olúwa.” Ó fi fún Ṣafani, ẹni tí ó kà á.
9 Nake Shafani ũcio mwandĩki-marũa agĩthiĩ kũrĩ mũthamaki na akĩmũhe ũhoro ũcio, akĩmwĩra atĩrĩ: “Anene aku nĩmarĩhĩte mbeeca iria ciarĩ hekarũ-inĩ ya Jehova, na nĩmaciĩhokeire kũrĩ aruti a wĩra na arũgamĩrĩri a hekarũ.”
Nígbà náà, Ṣafani akọ̀wé lọ sí ọ̀dọ̀ ọba. Ó sì sọ fún un pé, “Àwọn ìjòyè rẹ ti san owó náà tí ó wà nínú ilé Olúwa. Èmi sì ti fi lé ọwọ́ àwọn tí ó ń ṣe iṣẹ́ náà àti àwọn alábojútó nílé Olúwa.”
10 Ningĩ Shafani ũcio mwandĩki-marũa akĩĩra mũthamaki atĩrĩ, “Hilikia ũrĩa mũthĩnjĩri-Ngai, nĩanengera ibuku.” Nake Shafani akĩrĩthomera mũthamaki.
Nígbà náà Ṣafani akọ̀wé sọ fún ọba pé, “Hilkiah àlùfáà ti fún un ní ìwé kan.” Ṣafani kà lára rẹ̀ níwájú ọba.
11 Rĩrĩa mũthamaki aaiguire ciugo cia Ibuku rĩu rĩa Watho-rĩ, agĩtembũranga nguo ciake.
Nígbà tí ọba gbọ́ ọ̀rọ̀ tí ó wà nínú ìwé òfin, ó sì fa aṣọ rẹ̀ ya.
12 Akĩruta mawatho maya kũrĩ Hilikia ũrĩa mũthĩnjĩri-Ngai, na kũrĩ Ahikamu mũrũ wa Shafani, na Akiboru mũrũ wa Mikaia, na kũrĩ Shafani ũcio mwandĩki-marũa, na kũrĩ Asaia ũrĩa mũrori wa maũndũ ma mũthamaki, akĩmeera atĩrĩ:
Ó pa àṣẹ yìí fún Ahikamu àlùfáà, Hilkiah ọmọ Ṣafani, Akbori ọmọ Mikaiah, àti Ṣafani akọ̀wé àti Asaiah ìránṣẹ́ ọba.
13 “Thiĩi mũkanduĩrĩrie ũhoro kũrĩ Jehova, na mũtuĩrĩrie andũ, o na Juda yothe, ũrĩa kwandĩkĩtwo ibuku-inĩ rĩĩrĩ rĩonekete. Marakara ma Jehova nĩ maingĩ, marĩa maraakana nĩ ũndũ witũ, tondũ maithe maitũ matiaathĩkĩire ũhoro wa ibuku rĩĩrĩ; na matiekire kũringana na ũhoro ũrĩa wothe wandĩkĩtwo thĩinĩ warĩo ũrĩa ũtũkoniĩ.”
“Lọ, ẹ béèrè lọ́wọ́ Olúwa fún mi àti fún àwọn ènìyàn àti fún gbogbo Juda nípa ohun tí a kọ sínú ìwé yìí tí a ti rí. Títóbi ni ìbínú Olúwa tí ó ń jó sí wa nítorí àwọn baba wa kò tẹ̀lé ọ̀rọ̀ inú ìwé yìí; wọn kò ṣe ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí a kọ níbẹ̀ nípa wa.”
14 Hilikia ũrĩa mũthĩnjĩri-Ngai, na Ahikamu, na Akiboru, na Shafani, na Asaia magĩthiĩ kwaria na Hulida ũrĩa mũnabii mũndũ-wa-nja ũrĩa warĩ mũtumia wa Shalumu mũrũ wa Tikiva, mũrũ wa Harihasi ũrĩa warĩ mũmenyereri wa nguo cia mũthamaki, Hulida aatũũraga Jerusalemu, rũgongo rwa keerĩ.
Hilkiah àlùfáà, Ahikamu àti Akbori Ṣafani pẹ̀lú Asaiah, lọ sí ọ̀dọ̀ wòlíì obìnrin Hulda láti lọ bá a sọ̀rọ̀, ẹni tí ó jẹ́ aya Ṣallumu ọmọ Tikfa ọmọ Harhasi alábojútó ibi ìpa aṣọ mọ́ sí. Ó ń gbé ní Jerusalẹmu ní ìdàkejì.
15 Nake akĩmeera atĩrĩ, “Ũũ nĩguo Jehova Ngai wa Isiraeli ekuuga: Ĩrai mũndũ ũrĩa ũmũtũmĩte kũrĩ niĩ atĩrĩ,
Ó wí fún wọn pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí, Sọ fún ọkùnrin tí ó rán an yín sí mi,
16 ‘Ũũ nĩguo Jehova ekuuga: Nĩngũrehithia mwanangĩko kũndũ gũkũ na kũrĩ andũ akuo kũringana na maũndũ marĩa mothe mandĩkĩtwo ibuku-inĩ rĩrĩa mũthamaki wa Juda athomete.
‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí: Èmi yóò mú ibi wá sí ibí àti àwọn ènìyàn rẹ ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí a kọ sínú ìwé tí ọba Juda ti kà.
17 Tondũ nĩmandirikĩte, na magacinĩra ngai ingĩ ũbumba, na makaandakaria nĩ ũndũ wa mĩhianano yothe ĩrĩa mathondekete na moko mao, marakara makwa nĩmakanĩire kũndũ gũkũ, na matingĩhoreka.’
Nítorí tí wọ́n ti kọ̀ mí sílẹ̀, wọ́n sì tún sun tùràrí fún ọlọ́run mìíràn. Wọ́n sì mú mi bínú nípa gbogbo àwọn òrìṣà tí wọ́n ti fi ọwọ́ wọn dá. Ìbínú mi yóò ru sí ibí yìí, kì yóò sì rọlẹ̀.’
18 Ĩrai mũthamaki wa Juda, ũrĩa ũmũtũmĩte mũũke mũtuĩrie ũhoro kũrĩ Jehova atĩrĩ, ‘Jehova Ngai wa Isiraeli ekuuga atĩrĩ ũhoro wĩgiĩ ciugo iria ũiguĩte:
Sọ fún ọba Juda tí ó rán yín láti béèrè lọ́wọ́ Olúwa, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí nípa ọ̀rọ̀ wọ̀n-ọn-nì tí ìwọ ti gbọ́.
19 Tondũ ngoro yaku nĩyaherire na ũkĩĩnyiihĩria Jehova rĩrĩa waiguire ũhoro ũrĩa njarĩtie wa gũũkĩrĩra kũndũ gũkũ o na andũ akuo, atĩ nĩmakanyiitwo nĩ kĩrumi na mwanangĩko, na tondũ nĩwatembũrangire nguo ciaku na ũkĩrĩra ũrĩ mbere yakwa-rĩ, nĩngũiguĩte, ũguo nĩguo Jehova ekuuga.
Nítorí tí ọkàn rẹ rọ̀, tí ìwọ sì ti rẹ ara rẹ sílẹ̀ níwájú Olúwa, nígbà tí ìwọ gbọ́ èyí tí mo sọ sí ibí yìí àti sí àwọn ènìyàn rẹ pé wọn yóò di ahoro àti ẹni ègún tí ìwọ sì fa aṣọ ọ̀ rẹ ya pẹ̀lú níwájú mi. Èmi ti gbọ́ tìrẹ, ni Olúwa wí.
20 Nĩ ũndũ ũcio nĩngagũcookanĩrĩria hamwe na maithe maku, na nĩũgathikwo na thayũ. Maitho maku matikoona mwanangĩko ũrĩa ngaarehe kũndũ gũkũ.’” Nĩ ũndũ ũcio magĩcookeria mũthamaki ũhoro ũcio.
Nítorí náà èmi yóò kó ọ jọ sí ọ̀dọ̀ àwọn baba à rẹ, a ó sì sin ọ́ ní àlàáfíà. Ojú rẹ kì yóò rí gbogbo àwọn ibi tí èmi yóò mú wá bá ibí yìí.’” Bẹ́ẹ̀ wọ́n mú èsì rẹ̀ padà tọ ọba wá.