< 2 Maũndũ 6 >
1 Ningĩ Solomoni akiuga atĩrĩ, “Jehova oigĩte atĩ arĩikaraga thĩinĩ wa itu rĩrĩa itumanu.
Nígbà náà ni Solomoni wí pé, “Olúwa ti sọ wí pé òun yóò máa gbé nínú òkùnkùn tí ó ṣú biribiri;
2 No rĩrĩ, nĩngwakĩire hekarũ kĩĩrorerwa, handũ haku ha gũtũũra nginya tene.”
ṣùgbọ́n èmi ti kọ́ tẹmpili dáradára fún ọ ibi tí ìwọ yóò máa gbé títí láé.”
3 O hĩndĩ ĩyo, kĩũngano gĩothe gĩa Isiraeli kĩrũgamĩte hau, mũthamaki agĩkĩhũgũkĩra na agĩkĩrathima.
Ní ìgbà tí gbogbo ìjọ Israẹli dúró níbẹ̀, ọba yíjú padà ó sì fi ìbùkún fún gbogbo wọn.
4 Ningĩ akiuga atĩrĩ: “Jehova arogoocwo, o we Ngai wa Isiraeli, ũrĩa ũhingĩtie na moko make ũrĩa erĩire baba Daudi na kanua gake mwene. Nĩgũkorwo oigĩte atĩrĩ,
Nígbà náà ni ó sì wí pé: “Ògo ni fún Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, tí ó fi ọwọ́ rẹ̀ mú ohun tí ó fi ẹnu rẹ̀ sọ fún Dafidi baba mi ṣẹ. Nítorí tí ó wí pé,
5 ‘Kuuma mũthenya ũrĩa ndaarutire andũ akwa Misiri, ndirĩ ndathuura itũũra inene mũhĩrĩga-inĩ o na ũmwe wa Isiraeli atĩ nĩguo njakĩrwo hekarũ ĩtanĩtio na Rĩĩtwa rĩakwa kuo, o na kana ngaathuura mũndũ o na ũrĩkũ atuĩke wa gũtongoria andũ akwa a Isiraeli.
‘Láti ọjọ́ tí èmi ti mú àwọn ènìyàn mi jáde kúrò ní ilẹ̀ Ejibiti, èmi kò yan ìlú kan nínú gbogbo ẹ̀yà Israẹli, láti kọ́ ilé, kí orúkọ mi kí ó lè wà níbẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni èmi kò yan ẹnikẹ́ni láti jẹ́ olórí lórí Israẹli ènìyàn mi.
6 No rĩrĩ, nĩthuurĩte Jerusalemu nĩguo Rĩĩtwa rĩakwa rĩikarage kuo, na nĩ thuurĩte Daudi athamakĩre andũ akwa a Isiraeli.’
Ṣùgbọ́n nísinsin yìí èmi ti yan Jerusalẹmu, kí orúkọ mi le è wà níbẹ̀, èmi sì ti yan Dafidi láti jẹ ọba lórí Israẹli ènìyàn mi.’
7 “Baba Daudi nĩatuĩte na ngoro yake gwaka hekarũ ĩĩtanĩtio na Rĩĩtwa rĩa Jehova, o we Ngai wa Isiraeli.
“Baba mi Dafidi ti ní-in lọ́kàn láti kọ́ tẹmpili fún orúkọ Olúwa, àní Ọlọ́run Israẹli.
8 No Jehova eerire baba Daudi atĩrĩ, ‘Tondũ nĩwaatuĩte na ngoro yaku kũnjakĩra hekarũ ĩtanĩtio na Rĩĩtwa rĩakwa-rĩ, nĩ wekire wega nĩ gwĩciiria ũguo ngoro-inĩ yaku.
Ṣùgbọ́n Olúwa sọ fún Dafidi baba mi pé, ‘Nítorí tí ó wà ní ọkàn rẹ láti kọ́ tẹmpili yìí fún orúkọ mi, ìwọ ṣe ohun dáradára láti ní èyí ní ọkàn rẹ̀.
9 No rĩrĩ, wee tiwe ũgwaka hekarũ ĩyo, no nĩ mũrũguo ũrĩa uumĩte mũthiimo waku na thakame-inĩ yaku, ũcio nĩwe ũkaanjakĩra hekarũ ĩtanĩtio na Rĩĩtwa rĩakwa.’
Ṣùgbọ́n síbẹ̀, ìwọ kọ́ ni yóò kọ́ tẹmpili náà, bí kò ṣe ọmọ rẹ, ẹni tí o jẹ́ ẹran-ara àti ẹ̀jẹ̀ rẹ: òun ni yóò kọ́ tẹmpili fún orúkọ mi.’
10 “Jehova nĩatũũrĩtie kĩrĩkanĩro kĩrĩa eeranĩire. Nĩnjookete ithenya rĩa baba Daudi, na rĩu nĩnjikarĩire gĩtĩ gĩa ũthamaki gĩa Isiraeli, o ta ũrĩa Jehova eeranĩire, na nĩnjakĩte hekarũ ĩrĩa ĩtanĩtio na Rĩĩtwa rĩa Jehova, Ngai wa Isiraeli.
“Olúwa sì ti mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ. Èmi ti dìde ní ipò Dafidi baba mi, a sì gbé mi ka ìtẹ́ Israẹli, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti ṣe ìlérí, èmi sì ti kọ́ tẹmpili fún orúkọ Olúwa, Ọlọ́run Israẹli.
11 Hau nĩho njigĩte ithandũkũ rĩa kĩrĩkanĩro rĩrĩa rĩigĩtwo kĩrĩkanĩro kĩrĩa Jehova aarĩkanĩire na andũ a Isiraeli.”
Níbẹ̀ ni èmi sì gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa sí, nínú èyí ti májẹ̀mú ti Olúwa bá àwọn Israẹli ènìyàn mi dá wà.”
12 Ningĩ Solomoni akĩrũgama mbere ya kĩgongona kĩa Jehova o hau mbere ya kĩũngano gĩothe gĩa Isiraeli, agĩtambũrũkia moko make.
Nígbà náà ni Solomoni dúró níwájú pẹpẹ Olúwa, ní iwájú gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli, ó sì tẹ́ ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì.
13 Na rĩrĩ, Solomoni nĩathondekete rũtara rwa gĩcango rwa mĩkono ĩtano kũraiha, na mĩkono ĩtano kwarama, na mĩkono ĩtatũ kũraiha na igũrũ, na akĩrũiga gatagatĩ ka nja ĩyo. Akĩrũgama rũtara-inĩ igũrũ na agĩturia maru mbere ya kĩũngano kĩu gĩothe gĩa Isiraeli na akĩambararia moko make na igũrũ.
Solomoni ṣe àga idẹ kan tí ó jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ márùn-ún ní gígùn àti ìgbọ̀nwọ́ márùn-ún fífẹ̀ àti ìgbọ̀nwọ́ mẹ́ta ní gíga, a gbé e sí àárín àgbàlá ti òde. Ó sì dúró ní orí rẹ̀, àti pé ó kúnlẹ̀ lórí eékún rẹ̀ níwájú gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli, ó sì tẹ́ ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì sí òkè ọ̀run.
14 Nake akiuga atĩrĩ: “Wee Jehova, Ngai wa Isiraeli, gũtirĩ Ngai ũngĩ ũhaana tawe, kũu igũrũ kana gũkũ thĩ, o Wee ũhingagia kĩrĩkanĩro gĩaku kĩa wendo harĩ ndungata ciaku iria irũmagĩrĩra njĩra yaku na ngoro ciao ciothe.
Ó wí pé: “Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, kò sí Ọlọ́run tí ó dàbí rẹ ní ọ̀run àti ní ayé: ìwọ tí o pa májẹ̀mú ìfẹ́ rẹ mọ́ pẹ̀lú àwọn ìránṣẹ́ rẹ tí ń fi tọkàntọkàn wọn rìn ní ọ̀nà rẹ.
15 Wee nĩũhingĩirie baba Daudi, ndungata yaku, kĩrĩkanĩro gĩaku; ũndũ ũrĩa weranĩire na kanua gaku nĩũhingĩtie na guoko gwaku, o ta ũrĩa kũhaana ũmũthĩ.
Ìwọ tí o pa ìlérí tí o ṣe pẹ̀lú ìránṣẹ́ rẹ Dafidi baba mi mọ́; nítorí ìwọ ti fi ẹnu rẹ ṣe ìlérí àti pé ìwọ ti fi ọwọ́ rẹ mú un ṣẹ; bí ó ti rí lónìí yìí.
16 “Na rĩrĩ, Jehova, Ngai wa Isiraeli, hingĩria ndungata yaku baba, Daudi, ciĩranĩro iria wamwĩrĩire rĩrĩa woigire atĩrĩ, ‘Ndũkaaga mũndũ wa gũikarĩra gĩtĩ kĩa ũnene gĩa Isiraeli arĩ mbere yakwa, angĩkorwo ariũ aku nĩmarĩthiiaga na mĩthiĩre yagĩrĩire mbere yakwa kũringana na watho wakwa o ta ũrĩa wee ũtũire ũthiiaga.’
“Nísinsin yìí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, pa ìlérí tí ó ti ṣe mọ́ fún ìránṣẹ́ rẹ Dafidi baba mi nígbà tí o wí pé, ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ fẹ́ kù láti ní ọkùnrin láti jókòó níwájú mi lórí ìtẹ́ Israẹli, kìkì bí àwọn ọmọ rẹ tí wọ́n bá kíyèsi ara nínú gbogbo ohun tí wọ́n ṣe láti rìn níwájú mi gẹ́gẹ́ bí òfin mi gẹ́gẹ́ bí o sì ti ṣe.’
17 Na rĩrĩ, Wee Jehova, Ngai wa Isiraeli, reke kiugo gĩaku kĩrĩa werĩire ndungata yaku Daudi kĩhinge.
Nísinsin yìí, Olúwa Ọlọ́run Israẹli, jẹ́ kí ọ̀rọ̀ rẹ tí o ti ṣèlérí fún ìránṣẹ́ rẹ Dafidi kí ó wá sí ìmúṣẹ.
18 “No kũhoteke Ngai agĩtũũranie na andũ gũkũ thĩ? Igũrũ, o na kũũrĩa igũrũ mũno-rĩ, wee ndũngĩiganĩra kuo. Hekarũ ĩno njakĩte-rĩ, ndĩkĩrĩ nini makĩria?
“Ṣùgbọ́n ṣé Ọlọ́run nítòótọ́ yóò máa bá àwọn ènìyàn gbé lórí ilẹ̀ ayé bí? Ọ̀run àti ọ̀run gíga kò le gbà ọ́. Báwo ni ó ṣe kéré tó, ilé Olúwa tí mo ti kọ́!
19 No o na kũrĩ ũguo-rĩ, thikĩrĩria ihooya rĩa ndungata yaku, ĩgĩthaithana ĩiguĩrwo tha, Wee Jehova Ngai wakwa. Igua gũkaya na ihooya rĩrĩa ndungata yaku ĩrakũhooya ĩrĩ mbere yaku.
Síbẹ̀ ṣe àfiyèsí àdúrà ìránṣẹ́ rẹ àti ẹ̀bẹ̀ rẹ̀ fún àánú, Olúwa Ọlọ́run mi, gbọ́ ẹkún àti àdúrà tí ìránṣẹ́ rẹ̀ ń gbà níwájú rẹ.
20 Maitho maku maroikara marorete hekarũ ĩno mũthenya na ũtukũ, o handũ haha wee woigire atĩ nĩũgatũma Rĩĩtwa rĩaku rĩkoragwo ho. Ũroigua ihooya rĩrĩa ndungata yaku ĩrĩhooyaga ĩrorete handũ haha.
Kí ojú rẹ kí ó lè ṣí sí ilé Olúwa ní ọ̀sán àti lóru, ní ibí yìí tí ìwọ ti wí pé ìwọ yóò fi orúkọ rẹ síbẹ̀. Kí ìwọ kí ó gbọ́ àdúrà tí ìránṣẹ́ rẹ ń gbà lórí ibí yìí.
21 Igua gũthaithana kwa ndungata yaku na kwa andũ aku a Isiraeli rĩrĩa mekũhooya marorete handũ haha. Ũigue ũrĩ kũu igũrũ, o kũu gĩikaro gĩaku; na watũigua-rĩ, ũgatũrekera.
Gbọ́ ẹ̀bẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ àti ti àwọn ènìyàn Israẹli nígbà tí wọ́n bá ń gbàdúrà lórí ibí yìí. Gbọ́ láti ọ̀run, ibùgbé rẹ, nígbà tí ìwọ bá sì gbọ́, dáríjì.
22 “Rĩrĩa mũndũ angĩhĩtĩria mũndũ wa itũũra rĩake na gũtuĩke no nginya ehĩte, nake oke ehĩtĩre hau mbere ya kĩgongona gĩaku kĩa hekarũ-inĩ ĩno-rĩ,
“Nígbà tí ọkùnrin kan bá dẹ́ṣẹ̀ sí ẹnìkejì rẹ̀, tí a sì mú búra, tí ó sì búra níwájú pẹpẹ rẹ nínú ilé yìí,
23 hĩndĩ ĩyo ũkaigua ũrĩ o kũu igũrũ, na ũtue itua. Tuithania ndungata ciaku ciira, ũtũme ũrĩa ũhĩtĩirie ũrĩa ũngĩ acookererwo nĩ mahĩtia make marĩa ekĩte. Nake ũrĩa ũtehĩtie ũmũtue ndehĩtie na ũndũ ũcio wonanie atĩ ti mwĩhia.
nígbà náà, gbọ́ láti ọ̀run kí o sì dáhùn. Ṣe ìdájọ́ láàrín àwọn ìránṣẹ́ rẹ, san padà fún ẹni tí ó jẹ̀bi nípa mímú padà wá sí orí òun tìkára rẹ̀ ohun tí ó ti ṣe. Ṣe ìdáláre fún olódodo, bẹ́ẹ̀ sì ni, fi fún un gẹ́gẹ́ bí òdodo rẹ̀.
24 “Rĩrĩa andũ aku a Isiraeli maahootwo nĩ thũ tondũ nĩmakũhĩtĩirie nao magũcookerere na moimbũre rĩĩtwa rĩaku, mahooe magĩgũthaithaga marĩ hekarũ-inĩ ĩno-rĩ,
“Nígbà tí àwọn ènìyàn rẹ Israẹli bá ní ìjákulẹ̀ níwájú àwọn ọ̀tá nítorí wọ́n ti dẹ́ṣẹ̀ sí ọ àti nígbà tí wọ́n bá sì yípadà, tí wọ́n sì jẹ́wọ́ orúkọ rẹ, tí wọ́n gbàdúrà, tí wọ́n sì bẹ̀bẹ̀ níwájú rẹ nínú ilé Olúwa yìí,
25 hĩndĩ ĩyo ũkaamaigua ũrĩ o kũu igũrũ na ũrekere andũ aku a Isiraeli mehia mao na ũmacookie bũrũri ũrĩa wamaheire hamwe na maithe mao.
nígbà náà, ni kí o gbọ́ láti ọ̀run kí o sì dárí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn Israẹli jì wọ́n kí o sì mú wọn padà wá sílé tí o ti fi fún wọn àti àwọn baba wọn.
26 “Rĩrĩa igũrũ rĩkaahingwo, na mbura yaage kuura tondũ wa ũrĩa andũ aku makũhĩtĩirie, mangĩkaahooya marorete handũ haha, na moimbũre rĩĩtwa rĩaku na magarũrũke matigane na mehia mao tondũ nĩũmanyamarĩtie-rĩ,
“Nígbà tí a bá ti ọ̀run, tí kò sì sí òjò nítorí àwọn ènìyàn rẹ ti dẹ́ṣẹ̀ sí ọ, nígbà tí wọ́n bá sì gbàdúrà sí ibí yìí tí wọ́n sì jẹ́wọ́ orúkọ rẹ tí wọ́n sì yípadà kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ wọn nítorí ìwọ ti pọ́n wọn lójú,
27 hĩndĩ ĩyo ũkaamaigua ũrĩ o kũu igũrũ na ũrekere ndungata ciaku, andũ aku a Isiraeli, mehia mao. Marute mũtũũrĩre ũrĩa mwagĩrĩru, na ũmoirĩrie mbura bũrũri-inĩ ũcio waheire andũ aku ũtuĩke igai rĩao.
nígbà náà gbọ́ láti ọ̀run kí o sì dárí ẹ̀ṣẹ̀ jì àwọn ìránṣẹ́ rẹ, àwọn ènìyàn Israẹli kọ́ wọn ní ọ̀nà tí ó tọ́ nínú èyí tí wọn ó máa rìn, kí o sì rọ òjò sórí ilẹ̀ tí o ti fi fún àwọn ènìyàn rẹ fún ìní.
28 “Kũngĩkaagĩa ngʼaragu kana mũthiro bũrũri-inĩ, kana mĩgũnda ĩhĩe nĩ mbaa kana mbuu, kana gũũke ngigĩ kana ngũnga, kana thũ imarigiicĩrie itũũra-inĩ rĩmwe rĩao, na mwanangĩko o na ũrĩkũ kana mũrimũ ũngĩgooka-rĩ,
“Nígbà tí ìyàn tàbí àjàkálẹ̀-ààrùn bá wá sí ilẹ̀ náà, ìrẹ̀dànù tàbí ìmúwòdù, eṣú tàbí ẹlẹ́ǹgà, tàbí nígbà tí àwọn ọ̀tá wọn bá yọ wọ́n lẹ́nu nínú ọ̀kan lára àwọn ìlú wọn, ohunkóhun, ìpọ́njú tàbí ààrùn lè wá.
29 na rĩrĩa mũndũ o na ũrĩkũ wa andũ aku a Isiraeli, angĩkaahooya kana athaithane, nĩ ũndũ wa mũndũ kũmenya mĩnyamaro ĩrĩa arĩ nayo, o na ruo, na atambũrũkie moko make amerekeirie hekarũ-inĩ ĩno,
Nígbà tí àdúrà tàbí ẹ̀bẹ̀ bá sì wá láti ọ̀dọ̀ ẹnikẹ́ni àwọn ènìyàn rẹ Israẹli olúkúlùkù mọ̀ nípa ìpọ́njú rẹ̀ àti ìbànújẹ́, tí ó sì tẹ́ ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì sí ìhà ilé Olúwa yìí.
30 hĩndĩ ĩyo ũkaamaigua ũrĩ o kũu igũrũ gĩikaro-inĩ gĩaku, ũmarekere na ũtuĩre o mũndũ itua kũringana na ũrĩa wothe ekĩte, tondũ we nĩũĩ ngoro yake nĩgũkorwo nowe wiki ũũĩ ngoro cia andũ,
Nígbà náà gbọ́ láti ọ̀run ibùgbé rẹ dáríjì, kí o sì pín fún olúkúlùkù ènìyàn gẹ́gẹ́ bí i gbogbo ohun tí ó ṣe, nígbà tí ìwọ ti mọ ọkàn rẹ̀ (nítorí ìwọ nìkan ni ó mọ ọkàn ènìyàn.)
31 nĩgeetha matũũre magwĩtigĩrĩte, na mathiiage na mĩthiĩre yaku rĩrĩa rĩothe marĩtũũraga bũrũri-inĩ ũyũ waheire maithe maitũ.
Bẹ́ẹ̀ ni kí wọn kí ó lè bẹ̀rù rẹ kí wọn kí ó sì rìn ní ọ̀nà rẹ ní gbogbo ìgbà tí wọ́n ń gbé nínú ilé tí o ti fi fún àwọn baba wa.
32 “Ha ũhoro wa mũndũ wa kũngĩ ũrĩa ũtarĩ wa andũ aku a Isiraeli no nĩ oimĩte bũrũri wa kũraya nĩ ũndũ wa ngumo ya rĩĩtwa rĩaku inene na ũhoro wa ciĩko cia guoko gwaku kũrĩ hinya gũtambũrũkĩtio, rĩrĩa agooka ahooe erekeire hekarũ ĩno,
“Ní ti àwọn àlejò tí wọn kò sí lára àwọn ènìyàn rẹ Israẹli ṣùgbọ́n tí wọ́n wá láti ọ̀nà jíjìn nítorí orúkọ ńlá rẹ àti ọwọ́ agbára rẹ àti nínà apá rẹ, nígbà tí ó bá wá tí ó sì gbàdúrà pẹ̀lú kíkojú si ilé Olúwa yìí.
33 hĩndĩ ĩyo ũkaamũigua ũrĩ o kũu igũrũ gĩikaro-inĩ gĩaku, na mũndũ ũcio wa kũngĩ ũkaamũhingĩria o ũrĩa agakũhooya, nĩgeetha andũ othe a thĩ mamenye rĩĩtwa rĩaku na magwĩtigĩre, o ta ũrĩa andũ aku a Isiraeli magwĩtigĩrĩte, na mamenye atĩ nyũmba ĩno njakĩte, ĩtanĩtio na Rĩĩtwa rĩaku.
Nígbà náà, gbọ́ láti ọ̀run àní láti ibi ibùgbé rẹ, kí o sì ṣe ohun tí àwọn àlejò béèrè lọ́wọ́ rẹ. Bẹ́ẹ̀ ni kí gbogbo àwọn ènìyàn ayé kí wọn lè mọ orúkọ rẹ kí wọn sì bẹ̀rù rẹ, gẹ́gẹ́ bí Israẹli ènìyàn rẹ ti ṣe, kí wọn kí ó sì lè mọ̀ wí pé ilé yìí tí èmi ti kọ, orúkọ rẹ ni ó ń jẹ́.
34 “Rĩrĩa andũ aku maathiĩ mbaara-inĩ kũrũa na thũ ciao o kũrĩa ũngĩmatũma, nao makũhooe merekeire itũũra rĩĩrĩ inene ũthuurĩte na hekarũ ĩno njakĩte ĩtanĩtio na Rĩĩtwa rĩaku,
“Nígbà tí àwọn ènìyàn rẹ bá lọ sójú ogun lórí àwọn ọ̀tá wọn, nígbàkígbà tí o bá rán wọn, tí wọ́n sì gbàdúrà sí ọ si ìhà ìlú yìí tí ìwọ ti yàn àti ilé Olúwa tí èmi ti kọ́ fún orúkọ rẹ.
35 hĩndĩ ĩyo ũkaigua mahooya mao na gũthaithana kwao ũrĩ kũu igũrũ, na ũmatirĩrĩre ũhoro-inĩ ũcio wao.
Nígbà náà gbọ́ àdúrà wọn àti ẹ̀bẹ̀ wọn láti ọ̀run, kí o sì mú ọ̀rọ̀ wọn dúró.
36 “Rĩrĩa makwĩhĩria, nĩgũkorwo gũtirĩ mũndũ ũtehagia, nawe ũmarakarĩre ũmaneane kũrĩ thũ, nacio imatahe ĩmatware bũrũri wa kũraya kana wa gũkuhĩ;
“Nígbà tí wọ́n bá sì dẹ́ṣẹ̀ sí ọ—nítorí kò sí ènìyàn kan tí kì í dẹ́ṣẹ̀—bí o bá sì bínú sí wọn tí o bá sì fi wọ́n fún àwọn ọ̀tá, tí wọ́n kó wọn ní ìgbèkùn sí ilẹ̀ tí ó jìnnà réré tàbí nítòsí,
37 nao mangĩĩcookera ngoro-inĩ ciao marĩ o kũu bũrũri-inĩ ũrĩa maatahĩirwo, na merire, na magũthaithe marĩ o kũu maatahĩirwo, na moige atĩrĩ, ‘Nĩtwĩhĩtie, na nĩtwĩkĩte mahĩtia na tũgeka maũndũ ma waganu’;
ṣùgbọ́n, nígbà tí wọ́n bá sì yí ọkàn wọn padà ní ilẹ̀ tí wọ́n ti mú wọn ní ìgbèkùn, tí wọ́n sì ronúpìwàdà tí wọ́n sì bẹ̀bẹ̀ pẹ̀lú rẹ ní ilẹ̀ ìgbèkùn, wọn ó sì wí pé, ‘Àwa ti dẹ́ṣẹ̀, àwa sì ti ṣe ohun tí kò dára, a sì ti ṣe búburú’;
38 no mangĩgũcookerera na ngoro ciao ciothe na muoyo wao marĩ o bũrũri-inĩ ũrĩa maatahĩirwo, na mahooe merekeire bũrũri ũrĩa waheire maithe mao, na merekeire itũũra rĩrĩa inene rĩrĩa ũthuurĩte na merekeire hekarũ ĩno njakĩte ĩtanĩtio na Rĩĩtwa rĩaku;
tí wọn bá sì yípadà sí ọ pẹ̀lú gbogbo ọkàn àti ẹ̀mí ní ilẹ̀ ìgbèkùn wọn níbi tí wọ́n ti mú wọn, tí wọ́n sì gbàdúrà wọn, kojú si ìlú tí ìwọ ti yàn àti lórí ilé Olúwa tí mo ti kọ́ fún orúkọ rẹ;
39 hĩndĩ ĩyo ũrĩ o kũu igũrũ gĩikaro-inĩ gĩaku, ũkaigua ihooya rĩao na mathaithana mao na ũmatirĩrĩre ũhoro-inĩ ũcio wao. Na ũkaarekera andũ aku, o acio makwĩhĩirie.
nígbà náà, láti ọ̀run, ibi ibùgbé rẹ, gbọ́ àdúrà wọn àti ẹ̀bẹ̀ wọn, kí o sì mú ọ̀ràn wọn dúró, kí o sì dárí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn jì wọn, tí wọn ti dẹ́ṣẹ̀ sí ọ.
40 “Na rĩrĩ, Ngai wakwa, ũrohingũra maitho maku, o namo matũ maku mathikĩrĩrie mahooya marĩa marĩhooyagĩrwo handũ haha.
“Nísinsin yìí, Ọlọ́run mi, jẹ́ kí ojú rẹ kí ó ṣí kí o sì tẹ́ etí rẹ sílẹ̀ fún àdúrà sí ibí yìí.
41 “Rĩu gĩũkĩre, Wee Jehova Ngai, na ũũke handũ haku ha kũhurũka,
“Ǹjẹ́ nísinsin yìí dìde, Olúwa Ọlọ́run mi, sí ibi ìsinmi rẹ,
42 Wee Jehova Ngai, ndũgatiganĩrie ũrĩa waku mũitĩrĩrie maguta.
Olúwa Ọlọ́run mi, má ṣe kọ̀ ẹni àmì òróró rẹ.