< 2 Maũndũ 25 >

1 Amazia aarĩ wa mĩaka mĩrongo ĩĩrĩ na ĩtano rĩrĩa aatuĩkire mũthamaki, nake agĩthamaka arĩ kũu Jerusalemu mĩaka mĩrongo ĩĩrĩ na kenda, nake nyina eetagwo Jehoadini na oimĩte Jerusalemu.
Amasiah jẹ́ ẹni ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n nígbà tí ó di ọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kàndínlọ́gbọ̀n orúkọ ìyá rẹ̀ a máa jẹ́ Jehoadani, ó wá láti Jerusalẹmu.
2 Nĩekire maũndũ marĩa moonagwo magĩrĩire maitho-inĩ ma Jehova, no ndaamekire na ngoro yake yothe.
Ó ṣe ohun tí ó dára lójú Olúwa, ṣùgbọ́n kì í ṣe tọkàntọkàn.
3 Thuutha wa ũthamaki kũrũma wega wathani-inĩ wake, akĩũraga anene arĩa mooragĩte ithe Joashu ũrĩa warĩ mũthamaki.
Lẹ́yìn tí ìjọba ti wà ní ìdarí rẹ̀, ó pa àwọn oníṣẹ́ tí ó pa baba rẹ̀ ọba.
4 No rĩrĩ, ndaigana kũũraga ariũ ao, no eekire kũringana na ũrĩa kwandĩkĩtwo Ibuku-inĩ rĩa Watho wa Musa, harĩa Jehova aathanĩte atĩrĩ: “Maithe ma ciana matikooragwo nĩ ũndũ wa ciana, o na kana ciana ciũragwo nĩ ũndũ wa maithe mao; o mũndũ arĩkuaga nĩ ũndũ wa mehia make we mwene.”
Síbẹ̀ kò pa àwọn ọmọ wọn, ṣùgbọ́n ó ṣe ní ìbámu pẹ̀lú ohun tí a kọ nínú òfin nínú ìwé Mose, níbi tí Olúwa ti paláṣẹ pé, “A kò gbọdọ̀ pa àwọn baba fún àwọn ọmọ wọn tàbí àwọn ọmọ fún baba wọn, olúkúlùkù ni kí ó kú fún ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.”
5 Amazia agĩĩta andũ a Juda hamwe, na akĩmaiga maroragwo nĩ anene a ikundi cia andũ ngiri ngiri na anene a ikundi cia andũ igana, igana kũringana na nyũmba ciao cia andũ othe a Juda na Benjamini. Agĩcooka agĩĩta andũ othe arĩa maarĩ na ũkũrũ wa mĩaka mĩrongo ĩĩrĩ na makĩria na akĩona atĩ kwarĩ na andũ 300,000 arĩa mangĩathiire mbaara-inĩ, andũ mangĩahotire kuoya itimũ na ngo.
Amasiah, pe gbogbo àwọn ènìyàn Juda pọ̀, ó sì fi iṣẹ́ lé wọn lọ́wọ́ gẹ́gẹ́ bí ìdílé wọn sí àwọn alákòóso ẹgbẹẹgbẹ̀rún àti àwọn alákòóso ọ̀rọ̀ọ̀rún fún gbogbo Juda àti Benjamini, ó sì gbá iye wọn láti ẹni ogún ọdún àti jù bẹ́ẹ̀ lọ jọ, ó sì rí i pé ọ̀kẹ́ mẹ́ẹ̀ẹ́dógún àwọn ọkùnrin ni ó ti múra fún ìsìn ogun, tí ó lè gbá ọ̀kọ̀ àti àpáta mú.
6 O na ningĩ agĩkombora andũ a kũrũa 100,000 kuuma Isiraeli na thogora wa taranda igana rĩmwe cia betha.
Ó sì yá ọ̀kẹ́ márùn-ún àwọn ọkùnrin oníjà láti Israẹli fún ọgọ́rùn-ún àwọn tálẹ́ǹtì fàdákà.
7 No rĩrĩ, mũndũ wa Ngai agĩũka kũrĩ we, akĩmwĩra atĩrĩ, “Wee mũthamaki-rĩ, thigari ici cia kuuma Isiraeli itigatwarane nawe, nĩgũkorwo Jehova ndarĩ hamwe na Isiraeli, na ndarĩ hamwe na andũ o na arĩkũ a Efiraimu.
Ṣùgbọ́n ènìyàn Ọlọ́run kan tọ̀ ọ́ wá ó sì wí pé, “Ọba, àwọn ọ̀wọ́ ogun láti Israẹli kò gbọdọ̀ yan pẹ̀lú rẹ, nítorí tí Olúwa kò wà pẹ̀lú Israẹli kì í ṣe pẹ̀lú ẹnìkankan láti Efraimu.
8 O na ũngĩthiĩ ũrũe na ũcamba mbaara-inĩ, Ngai no arĩtũma ũhootwo nĩ thũ, nĩgũkorwo Ngai arĩ na ũhoti wa gũgũteithia kana wa gũtũma ũhootwo.”
Àní, tí ẹ bá lọ jà pẹ̀lú ìmúláyàle ní ojú ogun, Ọlọ́run yóò bì ọ́ ṣubú níwájú àwọn ọ̀tá, nítorí Ọlọ́run ní agbára láti ràn ọ́ lọ́wọ́ àti láti bì ọ́ ṣubú.”
9 Amazia akĩũria mũndũ wa Ngai atĩrĩ, “Tũgwĩka atĩa nĩ ũndũ wa taranda iria 100 ndarĩhire nĩ ũndũ wa thigari icio cia Isiraeli?” Nake mũndũ wa Ngai agĩcookia atĩrĩ, “Jehova no akũhe ingĩ nyingĩ gũkĩra icio.”
Amasiah sì bi ènìyàn Ọlọ́run pé, “Ọgọ́rùn-ún tálẹ́ǹtì tí mo ti san fún àwọn ọ̀wọ́ ogun àwọn ọmọ Israẹli ń kọ́?” Ènìyàn Ọlọ́run dáhùn pé “Olúwa lè fún ọ ní èyí tí ó ju ìyẹn lọ.”
10 Nĩ ũndũ ũcio Amazia akĩrekereria thigari icio ciokĩte kũrĩ we kuuma Efiraimu, agĩciĩra ciinũke. Nacio ikĩrakarĩra andũ a Juda mũno, na ikĩinũka irĩ na marakara maingĩ.
Bẹ́ẹ̀ ni Amasiah, tú àwọn ọwọ́ ogun tí ó ti wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀ láti Efraimu ká. Ó sì rán wọn lọ ilé. Wọ́n kún fún ìbínú pẹ̀lú Juda, wọ́n sì padà lọ ilé pẹ̀lú ìbínú ńlá.
11 Amazia agĩcooka akĩbanga thigari ciake, agĩcitongoria na mwena wa Gĩtuamba gĩa Cumbĩ, kũrĩa ooragire andũ 10,000 a Seiru.
Nígbà náà, Amasiah ko ogun rẹ jọ àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ lọ sí àfonífojì iyọ̀, níbi tí ó ti pa ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá àwọn ọkùnrin Seiri.
12 Mbũtũ ya ita ya Juda ĩkĩnyiita andũ 10,000 marĩ muoyo, na ĩkĩmatwara handũ igũrũ wa rwaro rwa ihiga, ĩkĩmaikia thĩ magĩthuthĩkanga.
Àwọn ọkùnrin Juda pẹ̀lú fi agbára mú àwọn ọkùnrin ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá láààyè. Wọ́n mú wọn lọ sí orí òkè bèbè òkúta, wọ́n jù wọ́n sílẹ̀, kí gbogbo wọn sì fọ́ sí wẹ́wẹ́.
13 Hĩndĩ o ĩyo, thigari iria Amazia aacookithĩtie akĩgiria ikarũe-rĩ, igĩtharĩkĩra matũũra ma Juda kuuma Samaria nginya Bethi-Horoni. Nacio ikĩũraga andũ 3,000 na igĩtaha indo nyingĩ mũno.
Ní báyìí àwọn ọ̀wọ́ ogun tí Amasiah ti rán lọ padà, tí wọn kò nípa nínú ogun gbógun sí àwọn ìlú Juda láti Samaria sí Beti-Horoni. Wọ́n pa ẹgbẹ̀rún mẹ́ta nínú wọn, wọ́n sì kó ọ̀pọ̀ ìkógun ńlá.
14 Rĩrĩa Amazia aacookire oimĩte kũũraga andũ a Edomu-rĩ, nĩainũkire na ngai cia andũ a Seiru. Agĩcirũgamia ta ngai ciake mwene, agĩciinamĩrĩra na agĩcirutĩra magongona ma njino.
Nígbà tí Amasiah padà láti ibi pípa àwọn ará Edomu, ó mú àwọn ọlọ́run àwọn ènìyàn Seiri padà wá. Ó gbé wọn kalẹ̀ gẹ́gẹ́ bi àwọn ọlọ́run tirẹ̀. Ó tẹríba fún wọn, ó sì rú ẹbọ fún wọn.
15 Marakara ma Jehova magĩakanĩra Amazia, na akĩmũtũmĩra mũnabii, ũrĩa wamũũririe atĩrĩ, “Nĩ kĩĩ gĩgũtũma ũhooe kĩrĩra kũrĩ ngai cia andũ acio, o iria itaangĩahotire kũhonokia andũ acio kuuma moko-inĩ maku?”
Ìbínú Olúwa ru sí Amasiah, ó sì rán wòlíì kan sí i, tí ó wí pé, “Kí ni ó dé tí ìwọ fi ń béèrè lọ́wọ́ àwọn ọlọ́run àwọn ènìyàn yìí, tí wọn kò le gba àwọn ènìyàn tiwọn kúrò lọ́wọ́ rẹ?”
16 O akĩaragia-rĩ, mũthamaki akĩmũũria atĩrĩ, “Nĩtũgũtuĩte mũtaari wa mũthamaki? Kira! Nĩ kĩĩ gĩgũtũma wende kwĩyũragithia?” Nĩ ũndũ ũcio mũnabii ũcio agĩkira, no akiuga atĩrĩ, “Nĩnjũũĩ atĩ Ngai nĩatuĩte itua gũkwananga, nĩ ũndũ nĩwĩkĩte ũndũ ũcio, na nĩwarega kũigua kĩrĩra gĩakwa.”
Bí ó ti n sọ̀rọ̀, ọba wí fún un pé, “Ṣé a yàn ọ́ ní olùgba ọba lámọ̀ràn ni? Dúró! Èéṣe tí a ó fi lù ọ́ bolẹ̀?” Bẹ́ẹ̀ ni, wòlíì náà dúró ṣùgbọ́n ó wí pé, “Èmi mọ̀ pé Ọlọ́run ti pinnu láti pa ọ́ run nítorí ìwọ ti ṣe èyí, ìwọ kò sì tẹ́tí sí ìmọ̀ràn mi.”
17 Thuutha wa Amazia mũthamaki wa Juda kũhooya kĩrĩra kuuma kũrĩ ataari ake-rĩ, agĩtũma ndũmĩrĩri ĩno ya njũgitano kũrĩ Jehoashu mũrũ wa Jehoahazu, mũrũ wa Jehu mũthamaki wa Isiraeli, akĩmwĩra atĩrĩ: “Ũka, tũcemanie, tuonane ũthiũ kwa ũthiũ.”
Lẹ́yìn tí Amasiah ọba Juda ti béèrè lọ́wọ́ àwọn olùdámọ̀ràn, ó rán ìpèníjà yìí sí Jehoaṣi ọmọ Jehoahasi ọmọ Jehu, ọba Israẹli pé, “Wá bá mi lójúkojú.”
18 No Jehoashu mũthamaki wa Isiraeli agĩcookeria Amazia mũthamaki wa Juda atĩrĩ, “Mahiũ ma nyeki-inĩ ma kũu Lebanoni nĩmatũmĩire mũtarakwa ndũmĩrĩri o kũu Lebanoni makĩwĩra atĩrĩ: ‘Heana mwarĩguo ahikio nĩ mũriũ wakwa.’ Hĩndĩ ĩyo nyamũ ya gĩthaka ya kũu Lebanoni ĩgĩũka ĩkĩrangĩrĩria mahiũ macio ma nyeki-inĩ na makinya mayo.
Ṣùgbọ́n Jehoaṣi ọba Israẹli fèsì padà sí Amasiah ọba Juda pé, “Koríko kékeré kan ní Lebanoni rán iṣẹ́ sí igi kedari ní Lebanoni, fi ọmọbìnrin rẹ fún ọmọkùnrin mi ní ìgbéyàwó. Nígbà náà, ẹhànnà ẹranko ènìyàn ni Lebanoni wá, ó sì tẹ òṣùṣú náà lábẹ́ ẹsẹ̀.
19 Wĩĩrĩte na ngoro atĩ nĩũrĩkĩtie gũtooria Edomu, na rĩu ũkeeyona na ũgetĩĩa. No ikara mũciĩ! Nĩ kĩĩ gĩgũtũma wĩrehere thĩĩna na wĩniinithie wee mwene o hamwe na andũ a Juda?”
Ìwọ wí fún ara à rẹ wí pé, ìwọ ti ṣẹ́gun Edomu àti nísinsin yìí ìwọ ní ìhàlẹ̀ àti ìgbéraga. Ṣùgbọ́n dúró ní ilé! Kí ni ó dé tí ìwọ fi ń wá wàhálà tí o sì fi ń fa ìṣubú rẹ àti ti Juda pẹ̀lú?”
20 O na kũrĩ ũguo-rĩ, Amazia ndaigana gũthikĩrĩria, nĩgũkorwo nĩ Ngai warutaga wĩra nĩguo amaneane moko-inĩ ma Jehoashu, tondũ andũ a Juda nĩmarongoragia ngai cia Edomu.
Amasiah, bí ó tì wù kí ó rí kò tẹ́tí nítorí Ọlọ́run ṣe é kí ó lè gbé wọn lé Jehoaṣi lọ́wọ́: nítorí wọ́n wá àwọn ọlọ́run Edomu.
21 Nĩ ũndũ ũcio Jehoashu mũthamaki wa Isiraeli akĩmatharĩkĩra. We na Amazia mũthamaki wa Juda makĩngʼethanĩra kũu Bethi-Shemeshu thĩinĩ wa Juda.
Bẹ́ẹ̀ ni Jehoaṣi, ọba Israẹli: òun àti Amasiah ọba Juda dojúkọ ara wọn ní Beti-Ṣemeṣi ní Juda.
22 Andũ a Juda makĩhũũrwo nĩ andũ a Isiraeli, na o mũndũ akĩũrĩra gwake mũciĩ.
Àwọn ọmọ Israẹli da Juda rú, gbogbo olúkúlùkù ènìyàn sì sálọ sí ìlú rẹ̀.
23 Nake Jehoashu mũthamaki wa Isiraeli akĩnyiita Amazia mũthamaki wa Juda, mũrũ wa Joashu, mũrũ wa Ahazia, o kũu Bethi-Shemeshu. Ningĩ Jehoashu akĩmũrehe Jerusalemu, na akĩmomora rũthingo rwa Jerusalemu kuuma Kĩhingo kĩa Efiraimu nginya Kĩhingo gĩa Koine, handũ ha buti ta 600 kũraiha.
Jehoaṣi ọba Israẹli fi agbára mú Amasiah ọba Juda, ọmọ Joaṣi ọmọ Ahasiah ní Beti-Ṣemeṣi. Nígbà náà Joaṣi mú u wá sí Jerusalẹmu. Ó sì wó ògiri Jerusalẹmu lulẹ̀ láti ẹnu-ọ̀nà Efraimu sí igun ẹnu-ọ̀nà apá kan títí ń lọ sí irinwó ìgbọ̀nwọ́ ní gígùn.
24 Nake akĩoya thahabu yothe na betha, na indo ciothe iria ciarĩ thĩinĩ wa hekarũ ya Ngai iria ciamenyagĩrĩrwo nĩ Obedi-Edomu, hamwe na igĩĩna cia nyũmba ya ũthamaki, na andũ arĩa maatahĩtwo, nake agĩcooka Samaria.
Ọba kó gbogbo wúrà àti fàdákà àti gbogbo ohun èlò tí wọ́n rí ni ilé Ọlọ́run tí ọ́ wà ní àbojútó Obedi-Edomu, lápapọ̀ pẹ̀lú àwọn ìṣúra ààfin àti àwọn ògo pẹ̀lú, ó sì padà lọ sí Samaria.
25 Amazia mũrũ wa Joashu mũthamaki wa Juda aatũũrire muoyo mĩaka ikũmi na ĩtano thuutha wa gĩkuũ kĩa Jehoashu mũrũ wa Jehoahazu mũthamaki wa Isiraeli.
Amasiah ọmọ Joaṣi ọba Juda gbé fún ọdún mẹ́ẹ̀ẹ́dógún lẹ́yìn ikú Jehoaṣi ọmọ Jehoahasi ọba Israẹli.
26 Ha ũhoro wa maũndũ marĩa mangĩ ma wathani wa Amazia kuuma kĩambĩrĩria nginya mũthia-rĩ, githĩ ti maandĩke ibuku-inĩ rĩa athamaki a Juda na Isiraeli?
Fún ti iṣẹ́ mìíràn ti ìjọba Amasiah láti ìbẹ̀rẹ̀ dé ìparí, ṣé a kò kọ wọ́n sínú ìwé àwọn ọba Juda àti Israẹli?
27 Kuuma hĩndĩ ĩrĩa Amazia aagarũrũkire agĩtiga kũrũmĩrĩra Jehova-rĩ, makĩmũciirĩrĩra mamũũkĩrĩre kũu Jerusalemu, nake akĩũrĩra Lakishi, no magĩtũma andũ mamũrũmĩrĩre o nginya Lakishi, makĩmũũragĩra kuo.
Láti ìgbà tí Amasiah ti yípadà kúrò láti máa tẹ̀lé Olúwa, wọ́n dìtẹ̀ sí i ní Jerusalẹmu, ó sì sálọ sí Lakiṣi ṣùgbọ́n, wọ́n rán àwọn ọkùnrin tẹ̀lé e lọ sí Lakiṣi, wọ́n sì pa á síbẹ̀.
28 Agĩcookio aigĩrĩirwo mbarathi igũrũ, na agĩthikwo hamwe na maithe Itũũra-inĩ Inene rĩa Juda.
A gbé e padà pẹ̀lú ẹṣin. A sì sin ín pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀ ní ìlú ńlá ti Juda.

< 2 Maũndũ 25 >