< 2 Maũndũ 18 >
1 Na rĩrĩ, Jehoshafatu aarĩ na indo nyingĩ na agatĩĩka mũno, nake agĩtuma ũthoni na Ahabu.
Nísinsin yìí Jehoṣafati sì ní ọrọ̀ àti ọlá púpọ̀, ó sì dá àna pẹ̀lú Ahabu nípa fífẹ́ ọmọ rẹ̀.
2 Mĩaka mĩnini yathira-rĩ, agĩikũrũka agĩthiĩ gũceerera Ahabu kũu Samaria. Nake Ahabu akĩmũthĩnjĩra ngʼondu nyingĩ na ngʼombe marĩ hamwe na andũ arĩa maarĩ nake, na akĩmũringĩrĩria matharĩkĩre Ramothu-Gileadi.
Lẹ́yìn ọjọ́ díẹ̀, ó sọ̀kalẹ̀ láti lọ bá Ahabu lálejò ní Samaria. Ahabu sì pa àgùntàn àti màlúù púpọ̀ fún àti àwọn ènìyàn tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ ó sì rọ̀ ọ́ láti dojú ìjà kọ Ramoti Gileadi.
3 Ahabu, mũthamaki wa Isiraeli akĩũria Jehoshafatu mũthamaki wa Juda atĩrĩ, “Nĩũgũthiĩ hamwe na niĩ tũgookĩrĩre Ramothu-Gileadi?” Nake Jehoshafatu akĩmũcookeria atĩrĩ, “Niĩ tũrĩ o ũndũ ũmwe nawe, o na andũ akwa no ta andũ aku; na nĩtũgaakorwo tũrĩ hamwe nawe kũu mbaara-inĩ”.
Ahabu ọba Israẹli sì béèrè lọ́wọ́ ọba Jehoṣafati, ọba Juda pé, “Ṣé ìwọ yóò lọ pẹ̀lú mi sí Ramoti Gileadi?” Jehoṣafati sì dá a lóhùn pé, “Èmi wà gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti ṣe wà, àti àwọn ènìyàn mi gẹ́gẹ́ bí ènìyàn rẹ àwa yóò pẹ̀lú rẹ nínú ogun náà”.
4 No Jehoshafatu agĩcooka akĩĩra mũthamaki wa Isiraeli atĩrĩ, “Amba ũtuĩrie na ũmenye ũtaaro wa Jehova.”
Ṣùgbọ́n Jehoṣafati náà sì tún wí fún ọba Israẹli pé, “Kọ́kọ́ béèrè lọ́wọ́ Olúwa.”
5 Nĩ ũndũ ũcio mũthamaki wa Isiraeli akĩũngania anabii 400, akĩmooria atĩrĩ, “Tũthiĩ tũkahũũrane na Ramothu-Gileadi kana ndigathiĩ?” Nao makĩmũcookeria makĩmwĩra atĩrĩ, “Thiĩ, nĩgũkorwo Ngai nĩekũneana itũũra rĩu moko-inĩ ma mũthamaki.”
Bẹ́ẹ̀ ọba Israẹli kó àwọn wòlíì papọ̀, irinwó ọkùnrin ó sì bi wọ́n pé, “Kí àwa kí lọ sí ogun Ramoti Gileadi tàbí kí èmi kí ó jọ̀wọ́ rẹ?” Wọ́n dáhùn pé, “Lọ, nítorí tí Ọlọ́run yóò fi lé ọba lọ́wọ́.”
6 Nowe Jehoshafatu akĩũria atĩrĩ, “Kaĩ gũkũ gũtarĩ mũnabii wa Jehova ũrĩa tũngĩũria ũhoro kuuma kũrĩ we?”
Ṣùgbọ́n Jehoṣafati béèrè pé, “Ṣé kò ha sí wòlíì Olúwa níbí ẹni tí àwa ìbá béèrè lọ́wọ́ rẹ̀?”
7 Mũthamaki wa Isiraeli agĩcookeria Jehoshafatu atĩrĩ, “Nĩ kũrĩ mũndũ ũmwe ũrĩa ũngĩtũtuĩrĩria ũhoro kuuma kũrĩ Jehova, no nĩndĩmũthũire tondũ gũtirĩ hĩndĩ andathagĩra ũndũ mwega, no maũndũ mooru hĩndĩ ciothe. Nake nĩwe Mikaia mũrũ wa Imula.” No Jehoshafatu agĩcookia atĩrĩ, “Mũthamaki ndagĩrĩirwo nĩ kuuga ũguo.”
Ọba Israẹli dá Jehoṣafati lóhùn pé, “Ọkùnrin kan wà síbẹ̀ lọ́dọ̀ ẹni tí àwa ìbá tún béèrè lọ́wọ́ Olúwa, ṣùgbọ́n èmi kórìíra rẹ̀ nítorí kò jẹ́ sọ àsọtẹ́lẹ̀ ohun rere kan nípa mi ṣùgbọ́n bí kò ṣe ohun búburú, ní gbogbo ìgbà òun náà ni Mikaiah ọmọ Imla.” Jehoṣafati sì dá lóhùn pé, “Ọba kò gbọdọ̀ sọ bẹ́ẹ̀.”
8 Nĩ ũndũ ũcio mũthamaki wa Isiraeli agĩĩta ũmwe wa anene ake, akĩmwĩra atĩrĩ, “Ndehera Mikaia mũrũ wa Imula narua.”
Bẹ́ẹ̀ ni ọba Israẹli pe ọ̀kan lára àwọn ìjòyè ó sì wí pé, “Ẹ mú Mikaiah ọmọ Imla kí ó yára wá.”
9 Hĩndĩ ĩyo mũthamaki wa Isiraeli na Jehoshafatu mũthamaki wa Juda, mehumbĩte nguo ciao cia ũthamaki, magĩikarĩra itĩ ciao cia ũnene hau kĩhuhĩro-inĩ kĩa ngano kĩrĩa kĩarĩ itoonyero-inĩ rĩa Samaria, nao anabii othe maarĩ ho makĩratha mohoro marĩ mbere yao.
Wọ́n wọ aṣọ ìgúnwà wọn, ọba Israẹli àti Jehoṣafati ọba Juda wọ́n jókòó sórí ìtẹ́ wọ́n ní ìta ẹnu-bodè Samaria, pẹ̀lú gbogbo àwọn wòlíì tí ń sọtẹ́lẹ̀ níwájú wọn.
10 Na rĩrĩ, Zedekia mũrũ wa Kenaana nĩathondekete hĩa cia kĩgera, nake akiuga atĩrĩ, “Jehova ekuuga ũũ: ‘Ici nĩcio mũgaatheeca Asuriata nacio nginya mũmaniine.’”
Nísinsin yìí Sedekiah ọmọ Kenaana sì ti ṣe ìwo irin, ó sì wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa sọ: ‘Pẹ̀lú èyí ìwọ yóò kan àwọn ará Siria títí ìwọ ó fi pa wọ́n run.’”
11 Nao anabii acio angĩ othe maarathaga o ũndũ ũmwe, makoiga atĩrĩ: “Tharĩkĩra Ramothu-Gileadi na nĩũgũtooria, tondũ Jehova nĩekũrĩneana moko-inĩ ma mũthamaki.”
Gbogbo àwọn wòlíì tí ó kù ni wọn ń sọtẹ́lẹ̀ ní àkókò kan náà. Wọ́n sì wí pé, “Dojúkọ Ramoti Gileadi ìwọ yóò sì ṣẹ́gun, nítorí Olúwa yóò fi lé ọba lọ́wọ́.”
12 Mũndũ ũrĩa watũmĩtwo ageete Mikaia akĩmwĩra ũũ, “Atĩrĩrĩ, anabii arĩa angĩ othe maarĩtie o ta mũndũ ũmwe, mararathĩra mũthamaki ũhootani. Reke kiugo gĩaku gĩtigakararanie na kĩao, na warie ũndũ mwega.”
Ìránṣẹ́ tí ó ti lọ pe Mikaiah sì wí fún un pé, “Ẹ wò ó, gẹ́gẹ́ bí ọkùnrin kan àti òmíràn wòlíì fi ẹnu kan sọ rere fún ọba. Jẹ́ kí ọ̀rọ̀ rẹ kí ó dàbí ọ̀kan nínú tiwọn, kí o sì sọ rere.”
13 Nowe Mikaia akiuga atĩrĩ, “Ti-itherũ o ta ũrĩa Jehova atũũraga muoyo, niĩ ngũmwĩra o ũrĩa Ngai wakwa ekunjĩĩra.”
Ṣùgbọ́n Mikaiah wí pe, “Gẹ́gẹ́ bí ó ti dájú pé Olúwa ń bẹ láààyè, èmi yóò sọ ohun tí Ọlọ́run mi sọ.”
14 Hĩndĩ ĩrĩa aakinyire-rĩ, mũthamaki akĩmũũria atĩrĩ, “Mikaia, tũthiĩ tũkahũũranĩre itũũra rĩa Ramothu-Gileadi, kana tũtigaathiĩ?” Nake Mikaia akĩmũcookeria atĩrĩ, “Rĩtharĩkĩre na ũhootane, tondũ nĩrĩkũneanwo moko-inĩ maku.”
Nígbà tí ó dé, ọba béèrè lọ́wọ́ rẹ̀, “Mikaiah, ṣe kí àwa ki ó lọ sí ogun ti Ramoti Gileadi, tàbí kí àwa kí ó fàsẹ́yìn?” Ó sì dáhùn pé, “Ẹ dojúkọ wọ́n kí ẹ sì ṣẹ́gun, nítorí a ó fi wọ́n lé yín lọ́wọ́.”
15 Mũthamaki akĩmwĩra atĩrĩ, “Nĩ maita maigana ngũtũũra ngwĩhĩtithagia ndũkae kũnjĩĩra ũhoro ũngĩ tiga ũhoro wa ma thĩinĩ wa rĩĩtwa rĩa Jehova?”
Ọba sì wí fún un pé, “Ìgbà mélòó ni èmi ó fi ọ́ búra láti sọ ohun kan fún mi bí kò ṣe ọ̀rọ̀ òtítọ́ ní orúkọ Olúwa?”
16 Nake Mikaia akĩmũcookeria atĩrĩ, “Ndĩronire andũ a Isiraeli othe mahurunjũkĩire irĩma-inĩ ta ngʼondu itarĩ na mũrĩithi, nake Jehova aroiga atĩrĩ, ‘Andũ aya matirĩ na mwathi. O mũndũ nĩarekwo ainũke gwake na thayũ.’”
Mikaiah sì dáhùn pé, “Mo rí gbogbo Israẹli túká kiri lórí àwọn òkè bí àgùntàn tí kò ní olùṣọ́, Olúwa sì wí pé, ‘Àwọn wọ̀nyí kò ní olúwa. Jẹ́ kí olúkúlùkù padà sí ilé rẹ̀ ní àlàáfíà.’”
17 Nake mũthamaki wa Isiraeli akĩĩra Jehoshafatu atĩrĩ, “Githĩ ndikwĩrire atĩ ndarĩ hĩndĩ angĩĩndathĩra ũhoro mwega, tiga o ũrĩa mũũru?”
Ọba Israẹli wí fún Jehoṣafati pé, “Ṣe èmi kò sọ fún ọ wí pé òun kò sọ àsọtẹ́lẹ̀ rere kankan nípa mi rí, ṣùgbọ́n búburú nìkan?”
18 Mikaia agĩthiĩ na mbere, akiuga atĩrĩ, “Nĩ ũndũ ũcio thikĩrĩria kiugo kĩa Jehova: Ndĩronire Jehova aikarĩire gĩtĩ gĩake kĩa ũnene, arĩ na mbũtũ yothe ya igũrũ ĩrũgamĩte ĩmũthiũrũrũkĩirie mwena wa ũrĩo na wa ũmotho.
Mikaiah tẹ̀síwájú pé, “Nítorí náà, gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa, mo rí Olúwa jókòó lórí ìtẹ́ rẹ̀ gbogbo ogun ọ̀run sì dúró lápá ọ̀tún àti lápá òsì.
19 Nake Jehova aroria atĩrĩ, ‘Nũũ ũkũheenereria Ahabu mũthamaki wa Isiraeli nĩguo atharĩkĩre Ramothu-Gileadi, nĩgeetha athiĩ agakuĩre kuo?’ “Ũmwe akiuga ũũ, na ũrĩa ũngĩ akiuga ũũ.
Olúwa sì wí pé, ‘Ta ni yóò tan Ahabu ọba Israẹli lọ sí Ramoti Gileadi kí ó sì lọ kú ikú rẹ̀ níbẹ̀?’ “Èkínní sì sọ tìhín, òmíràn sì sọ tọ̀hún.
20 Marigĩrĩrio-inĩ, roho ũmwe ũkiumĩra, ũkĩrũgama mbere ya Jehova, ũkiuga atĩrĩ, ‘Nĩ niĩ ngũmũheenereria.’ “Jehova akĩũria atĩrĩ, ‘Ũkũmũheenereria atĩa?’
Ní ìparí, ni ẹ̀mí kan wá síwájú, ó dúró níwájú Olúwa ó sì wí pé, ‘Èmi yóò tàn án.’ “‘Nípa ọ̀nà wo?’ Olúwa béèrè.
21 “Naguo roho ũcio ũkiuga atĩrĩ, ‘Nĩgũthiĩ ngũthiĩ nduĩke roho wa maheeni tũnua-inĩ twa anabii ake othe.’ “Nake Jehova akiuga atĩrĩ, ‘Wee nĩũkũhota kũmũheenereria. Thiĩ ũgeeke ũguo.’
“‘Èmi yóò lọ láti lọ di ẹ̀mí èké ní ẹnu gbogbo àwọn wòlíì.’ “‘Ìwọ yóò sì borí nínú ìtànjẹ rẹ̀ báyìí,’ ni Olúwa wí. ‘Lọ kí ó sì ṣe bẹ́ẹ̀.’
22 “Nĩ ũndũ ũcio Jehova nĩekĩrĩte roho wa maheeni tũnua-inĩ twa anabii aya aku. Jehova nĩagwathĩrĩirie mwanangĩko.”
“Bẹ́ẹ̀ ni nísinsin yìí Olúwa ti fi ẹ̀mí èké sí ẹnu àwọn wòlíì rẹ. Olúwa sì ti sọ ibi sí ọ.”
23 Hĩndĩ ĩyo Zedekia mũrũ wa Kenaana akĩambata na akĩringa Mikaia rũhĩ ũthiũ. Akĩmũũria atĩrĩ, “Kaĩ roho wa Jehova agereire kũ rĩrĩa oimire kũrĩ niĩ nĩguo aarie nawe?”
Nígbà náà Sedekiah ọmọ Kenaana lọ sókè ó sì gbá Mikaiah ní ojú. Ó sì béèrè pé, “Ní ọ̀nà wo ni ẹ̀mí Olúwa gbà kọjá lọ kúrò lọ́dọ̀ mi láti bá ọ sọ̀rọ̀?”
24 Mikaia agĩcookia atĩrĩ, “Nĩũkamenya mũthenya ũrĩa ũgaathiĩ kwĩhitha kanyũmba ka na thĩinĩ.”
Mikaiah sì dáhùn pé, “Ìwọ yóò ṣe ìwádìí ní ọjọ́ tí ìwọ yóò sá pamọ́ sínú ìyẹ̀wù.”
25 Mũthamaki wa Isiraeli agĩathana, akiuga atĩrĩ, “Oyai Mikaia mũmũcookie kũrĩ Amoni mwathi wa itũũra inene, na kũrĩ Joashu mũrũ wa mũthamaki,
Ọba Israẹli pa á láṣẹ pé, “Mú Mikaiah kí o sì ran padà sí Amoni olórí ìlú àti sí Joaṣi ọmọ ọba,
26 na mũmwĩre atĩrĩ, ‘Mũthamaki ekuuga ũũ: Mũndũ ũyũ nĩaikio njeera na ndakaheo kĩndũ gĩa kũrĩa tiga mũgate na maaĩ nginya rĩrĩa ngaacooka na thayũ.’”
Ó sì wí pé, ‘Èyí ni ohun tí ọba sọ, ẹ fi ènìyàn yìí sínú túbú kí ẹ má sì ṣe fún un ní ohunkóhun ṣùgbọ́n àkàrà àti omi títí tí èmi yóò fi dé ní àlàáfíà.’”
27 Mikaia akiuga atĩrĩ, “Ũngĩgaacooka na thayũ-rĩ, no gũtuĩkire atĩ Jehova ndaarĩtie na niĩ.” Agĩcooka akiuga atĩrĩ, “Iguai ũhoro wakwa inyuĩ andũ aya inyuothe!”
Mikaiah sì wí pe, “Tí ìwọ bá padà ní àlàáfíà, Olúwa kò sọ̀rọ̀ láti ọ̀dọ̀ mi.” Nígbà náà, ó sì fi kún un pé, “Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ mi, gbogbo ẹ̀yin ènìyàn!”
28 Nĩ ũndũ ũcio mũthamaki wa Isiraeli na Jehoshafatu mũthamaki wa Juda makĩambata nginya Ramothu-Gileadi.
Bẹ́ẹ̀ ni ọba Israẹli àti Jehoṣafati ọba Juda lọ sókè ní Ramoti Gileadi.
29 Nake mũthamaki wa Isiraeli akĩĩra Jehoshafatu atĩrĩ, “Nĩngũtoonya mbaara-inĩ ndĩĩgarũrĩte ndikamenyeke no wee wĩkĩre nguo cia ũthamaki.” Nĩ ũndũ ũcio mũthamaki wa Isiraeli akĩĩgarũra ndakamenyeke na agĩtoonya mbaara-inĩ.
Ọba Israẹli sọ fún Jehoṣafati pé, “Èmi yóò lọ sí ojú ìjà, ṣùgbọ́n ìwọ wọ aṣọ ìgúnwà rẹ.” Bẹ́ẹ̀ ni ọba Israẹli pa aṣọ rẹ̀ dà, ó sì lọ sí ojú ìjà.
30 Na rĩrĩ, mũthamaki wa Asuriata nĩathĩte anene ake a ngaari cia ita akameera atĩrĩ, “Mũtikarũe na mũndũ o na ũrĩkũ, mũnini kana mũnene, tiga o mũthamaki wa Isiraeli.”
Nísinsin yìí ọba Siria ti pàṣẹ fún àwọn olórí kẹ̀kẹ́ tí ó wà ní ọ̀dọ̀ rẹ̀ pé, “Ẹ má ṣe jà pẹ̀lú ẹnìkankan, èwe tàbí àgbà àyàfi ọba Israẹli.”
31 Rĩrĩa anene a mbũtũ cia ngaari cia ita moonire Jehoshafatu magĩĩciiria atĩrĩ, “Ũyũ nĩwe mũthamaki wa Isiraeli” Nĩ ũndũ ũcio makĩgarũrũka mamũtharĩkĩre, no Jehoshafatu agĩkaya, nake Jehova akĩmũteithia. Ngai akĩmaroria na kũngĩ, makĩmweherera,
Nígbà tí àwọn olórí kẹ̀kẹ́ rí Jehoṣafati, wọ́n rò wí pé, “Èyí ní ọba Israẹli.” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì yípadà láti bá a jà. Ṣùgbọ́n Jehoṣafati kégbe sókè, Olúwa sì ràn án lọ́wọ́. Ọlọ́run sì lé wọn kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀,
32 nĩgũkorwo rĩrĩa anene a ngaari cia ita moonire atĩ tiwe warĩ mũthamaki wa Isiraeli, magĩtiga gũthingatana nake.
Ó sì ṣe, nígbà tí olórí kẹ̀kẹ́ rí i wí pé kì í ṣe ọba Israẹli, wọ́n sì dáwọ́ lílé rẹ̀ dúró.
33 No mũndũ ũmwe akĩgeeta ũta wake, agĩikia mũguĩ o ro ũguo, naguo ũkĩratha mũthamaki wa Isiraeli o gatagatĩ-inĩ ka magathĩkanĩrio ma nguo yake ya mbaara. Nake mũthamaki akĩĩra mũtwarithia wa ngaari ya ita atĩrĩ, “Garũra ngaari ũndute mbaara-inĩ. Nĩndagurario.”
Ṣùgbọ́n ẹnìkan fa ọrun rẹ̀ láì pète, ó sì bá ọba Israẹli láàrín ìpàdé ẹ̀wù irin, ọba sì sọ fún olùtọ́jú kẹ̀kẹ́ rẹ̀ pé, “Yí ọwọ́ rẹ padà, kí o sì wà mí jáde kúrò lójú ìjà. Nítorí èmi ti gbọgbẹ́.”
34 Nayo mbaara ĩkĩneneha mũthenya wothe, na mũthamaki wa Isiraeli agĩĩtiirania ngaari-inĩ yake ya mbaara angʼetheire Asuriata o nginya hwaĩ-inĩ. Narĩo riũa rĩgĩthũa-rĩ, agĩkua.
Ní ọjọ́ pípẹ́, ìjà náà sì ń pọ̀ sí i, ọba Israẹli dúró nínú kẹ̀kẹ́ rẹ̀ kọjú sí àwọn ará Siria títí ó fi di àṣálẹ́. Lẹ́yìn náà ní àkókò ìwọ oòrùn, ó sì kú.