< 1 Samũeli 13 >

1 Na rĩrĩ, Saũlũ aarĩ wa mĩaka mĩrongo ĩtatũ rĩrĩa aatuĩkire mũthamaki, na agĩthamakĩra Isiraeli mĩaka mĩrongo ĩna na ĩĩrĩ.
Saulu sì jẹ́ ọmọ ọgbọ̀n ọdún nígbà tí ó jẹ ọba, ó sì jẹ ọba lórí Israẹli ní ọdún méjìlélógójì.
2 Saũlũ nĩathuurire andũ ngiri ithatũ kuuma Isiraeli; ngiri igĩrĩ magĩikara nake kũu Mikimashi na bũrũri ũrĩa ũrĩ irĩma wa Betheli, nao andũ ngiri maarĩ na Jonathani kũu Gibea ya Benjamini. Andũ arĩa angĩ akĩmeera mainũke kwao mĩciĩ.
Saulu yan ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ọkùnrin ní Israẹli, ẹgbẹ̀rún méjì sì wà lọ́dọ̀ rẹ̀ ní Mikmasi àti ní ìlú òkè Beteli ẹgbẹ̀rún kan sì wà lọ́dọ̀ Jonatani ní Gibeah ti Benjamini. Àwọn ọkùnrin tókù ni ó rán padà sí ilé e wọn.
3 Jonathani agĩtharĩkĩra irangĩro rĩa Afilisti kũu Geba, nao Afilisti makĩigua ũhoro ũcio. Hĩndĩ ĩyo Saũlũ akĩhuhithia karumbeta bũrũri wothe, akiuga atĩrĩ, “Ahibirania nĩ maigue!”
Jonatani sì kọlu ẹgbẹ́ ogun àwọn Filistini ní Gibeah, Filistini sì gbọ́ èyí. Nígbà náà ni Saulu fọn ìpè yí gbogbo ilẹ̀ náà ká, ó sì wí pé, “Jẹ́ kí àwọn Heberu gbọ́!”
4 Nĩ ũndũ ũcio ũhoro ũyũ ũkĩiguuo Isiraeli guothe, gũkĩĩrwo atĩrĩ, “Saũlũ nĩatharĩkĩire irangĩro rĩa Afilisti, na rĩrĩ, andũ a Isiraeli nĩmatuĩkĩte kĩndũ kĩnungu harĩ Afilisti.” Nao andũ magĩĩtwo nĩguo mongane na Saũlũ kũu Giligali.
Bẹ́ẹ̀ ni gbogbo Israẹli sì gbọ́ ìròyìn pé, “Saulu ti kọlu ẹgbẹ́ ogun àwọn Filistini, Israẹli sì di òórùn búburú fún àwọn Filistini.” Àwọn ènìyàn náà sì péjọ láti darapọ̀ mọ́ Saulu ní Gilgali.
5 Nao Afilisti makĩũngana nĩguo marũe na andũ a Isiraeli, marĩ na ngaari cia ita ngiri ithatũ, na atwarithia a ngaari icio ngiri ithatũ, nacio thigari ciao ciarĩ nyingĩ ta mũthanga ũrĩa ũrĩ hũgũrũrũ-inĩ cia iria. Nao makĩambata magĩthiĩ makĩamba hema ciao kũu Mikimashi, mwena wa irathĩro wa Bethi-Aveni.
Àwọn Filistini kó ara wọn jọ pọ̀ láti bá Israẹli jà, pẹ̀lú ẹgbẹ̀rún mẹ́ta kẹ̀kẹ́, ẹgbẹ̀rún mẹ́fà ọkùnrin ẹlẹ́ṣin, àwọn ológun sì pọ̀ bí yanrìn etí Òkun. Wọ́n sì gòkè lọ, wọ́n dó ní Mikmasi ní ìhà ilẹ̀ oòrùn Beti-Afeni.
6 Hĩndĩ ĩrĩa andũ a Isiraeli moonire atĩ maarĩ handũ hooru mũno, na ita rĩao nĩrĩahatĩrĩirio mũno, makĩĩhitha ngurunga-inĩ na ihinga-inĩ, na gatagatĩ ka ndwaro cia mahiga, na thĩinĩ wa marima, o na marima-inĩ ma maaĩ.
Nígbà tí àwọn ọkùnrin Israẹli sì rí i pé àwọn wà nínú ìpọ́njú àti pé àwọn ológun wọn wà nínú ìhámọ́, wọ́n fi ara pamọ́ nínú ihò àti nínú igbó láàrín àpáta, nínú ọ̀fìn, àti nínú kànga gbígbẹ.
7 O na Ahibirania amwe nĩmaringire mũrĩmo wa Jorodani, magĩkinya bũrũri wa Gadi na Gileadi. Saũlũ we mwene aatigĩtwo Giligali, nacio mbũtũ ciothe cia ita iria ciarĩ hamwe nake nĩciainainaga nĩ guoya.
Àwọn Heberu mìíràn tilẹ̀ kọjá a Jordani sí ilẹ̀ Gadi àti Gileadi. Saulu wà ní Gilgali síbẹ̀, gbogbo àwọn ọ̀wọ́ ogun tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ sì ń wárìrì fún ìbẹ̀rù.
8 Nake agĩeterera mĩthenya mũgwanja ĩrĩa yatuĩtwo nĩ Samũeli; no Samũeli ndaigana gũũka Giligali, nao andũ a Saũlũ makĩambĩrĩria kũhurunjũka.
Ó sì dúró di ọjọ́ méje, àkókò tí Samuẹli dá; ṣùgbọ́n Samuẹli kò wá sí Gilgali, àwọn ènìyàn Saulu sì bẹ̀rẹ̀ sí ní túká.
9 Nĩ ũndũ ũcio Saũlũ akiuga atĩrĩ, “Ndeherai maruta ma igongona rĩa njino na maruta ma ũiguano.” Nake Saũlũ akĩruta igongona rĩa njino.
Saulu sì wí pé, “Ẹ mú ẹbọ sísun àti ẹbọ ìrẹ́pọ̀ wá fún mi.” Saulu sì rú ẹbọ sísun náà.
10 O rĩrĩa aarĩkirie kũruta igongona rĩu, Samũeli agĩkinya, nake Saũlũ agĩthiĩ kũmũtũnga amũgeithie.
Bí ó sì ti ń parí rírú ẹbọ sísun náà, Samuẹli sì dé, Saulu sì jáde láti lọ kí i.
11 Samũeli akĩmũũria atĩrĩ, “Nĩ atĩa weka?” Nake Saũlũ akĩmũcookeria atĩrĩ, “Rĩrĩa nyonire atĩ andũ nĩmarahurunjũka, nawe ndũnooka ihinda rĩrĩa rĩatuĩtwo, na atĩ Afilisti nĩmegwĩcookanagĩrĩria kũu Mikimashi-rĩ,
Samuẹli sì wí pé, “Kí ni ìwọ ṣe yìí.” Saulu sì dáhùn pé, “Nígbà tí mo rí pé àwọn ènìyàn náà ń túká, àti tí ìwọ kò sì wá ní àkókò ọjọ́ tí ìwọ dá, tí àwọn Filistini sì kó ara wọ́n jọ ní Mikmasi,
12 ndeciiria atĩrĩ, ‘Rĩu Afilisti nĩmegũikũrũka moke manjũkĩrĩre gũkũ Giligali, na ndithaithĩte Jehova nĩguo twĩtĩkĩrĩke nĩwe.’ Nĩ ũndũ ũcio ndaigua nĩnjagĩrĩirwo nĩkũruta igongona rĩa njino.”
mo rò pé, ‘Àwọn Filistini yóò sọ̀kalẹ̀ tọ̀ mí wá ní Gilgali nísinsin yìí, bẹ́ẹ̀ ni èmi kò ì tí ì wá ojúrere Olúwa.’ Báyìí ni mo mú ara mi ní ipá láti rú ẹbọ sísun náà.”
13 Samũeli akĩmwĩra atĩrĩ, “Nĩwĩkĩte ũndũ wa ũkĩĩgu. Ndũmenyereire rĩathani rĩrĩa Jehova Ngai waku aakũheire; korwo nĩwĩkĩte ũguo-rĩ, nĩangĩahaanda ũthamaki waku thĩinĩ wa Isiraeli ũtũũre tene na tene.
Samuẹli sì wí fún un pé, “Ìwọ hu ìwà aṣiwèrè, ìwọ kò sì pa òfin tí Olúwa Ọlọ́run rẹ fi fún ọ mọ́; bí o kò bá ṣe bẹ́ẹ̀, òun ìbá fi ìdí ìjọba rẹ kalẹ̀ lórí Israẹli láéláé.
14 No rĩu ũthamaki waku ndũgũtũũra; Jehova nĩacarĩtie mũndũ moimĩranĩtie ngoro, na akamũthuura atuĩke mũtongoria wa andũ ake, nĩ ũndũ ndũmenyereire watho wa Jehova.”
Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ìjọba rẹ kì yóò dúró pẹ́, Olúwa ti wá ọkùnrin tí ó wù ú ní ọkàn rẹ̀ fún ara rẹ̀, ó sì ti yàn án láti ṣe olórí fún àwọn ènìyàn rẹ̀, nítorí pé ìwọ kò pa òfin Olúwa mọ́.”
15 Hĩndĩ ĩyo Samũeli akiuma Giligali akĩambata Gibea ya Benjamini, nake Saũlũ agĩtara andũ arĩa aarĩ nao. Nao maarĩ ta andũ magana matandatũ.
Nígbà náà ni Samuẹli kúrò ní Gilgali, ó sì gòkè lọ sí Gibeah ti Benjamini, Saulu sì ka àwọn ènìyàn tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n sì jẹ́ ẹgbẹ̀ta.
16 Saũlũ na mũriũ Jonathani na andũ arĩa maarĩ nao maikaraga Gibea ya Benjamini, rĩrĩa Afilisti maambĩte hema ciao kũu Mikimashi.
Saulu àti ọmọ rẹ̀ Jonatani àti àwọn ènìyàn tí ó wà pẹ̀lú wọn dúró ní Gibeah ti Benjamini, nígbà tí àwọn Filistini dó ní Mikmasi.
17 Nacio ikundi cia atharĩkĩri ikiuma kambĩ-inĩ ya Afilisti irĩ ikundi ithatũ. Kĩmwe gĩkĩerekera mwena wa Ofara gũkuhĩ na Shuali,
Ẹgbẹ́ àwọn onísùmọ̀mí mẹ́ta jáde lọ ní àgọ́ àwọn Filistini ní ọnà ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀. Ẹgbẹ́ kan gba ọ̀nà ti Ofira ní agbègbè ìlú Ṣuali,
18 kĩrĩa kĩngĩ gĩkĩerekera Bethi-Horoni, na gĩa gatatũ gĩkĩerekera mũhaka-inĩ ũrĩa ũngʼetheire Kĩanda gĩa Zeboimu kĩrorete werũ-inĩ.
òmíràn gba ọ̀nà Beti-Horoni, ẹ̀kẹta sí ìhà ibodè tí ó kọjú sí àfonífojì Seboimu tí ó kọjú sí ijù.
19 Gũtiarĩ mũturi ũngĩonekire bũrũri wothe wa Isiraeli, tondũ Afilisti moigĩte atĩrĩ, “Mangĩgĩa nake, Ahibirania no mathondeke hiũ cia njora na matimũ!”
A kò sì rí alágbẹ̀dẹ kan ní gbogbo ilẹ̀ Israẹli, nítorí tí àwọn Filistini wí pé, “Bí kò ṣe bẹ́ẹ̀ àwọn Heberu yóò rọ idà tàbí ọ̀kọ̀!”
20 Nĩ ũndũ ũcio andũ othe a Isiraeli maikũrũkaga magathiĩ kũrĩ Afilisti, makanoorerwo hiũ ciao cia mĩraũ, na thururu, na mathanwa, na hiũ cia igetha.
Bẹ́ẹ̀ ni gbogbo Israẹli tọ àwọn Filistini lọ láti pọ́n dòjé wọn, ọ̀kọ̀, àáké àti ọ̀ṣọ́ wọn.
21 Thogora wa kũnoora hiũ cia mĩraũ na thururu warĩ cekeri icunjĩ igĩrĩ cia ithatũ, naguo thogora wa kũnoora theeci, na mathanwa, na kũrũnga mĩcengi warĩ cekeri gĩcunjĩ kĩmwe gĩa ithatũ.
Iye tí wọ́n fi pọ́n dòjé àti ọ̀kọ̀ jẹ́ ọwọ́ méjì nínú ìdámẹ́ta ṣékélì, àti ìdámẹ́ta ṣékélì fún pípọ́n òòyà-irin tí ilẹ̀, àáké àti irin ọ̀pá olùṣọ́ màlúù.
22 Nĩ ũndũ ũcio mũthenya wa mbaara gũtirĩ mũthigari o na ũmwe wa arĩa maarĩ na Saũlũ na Jonathani warĩ na rũhiũ rwa njora kana itimũ guoko-inĩ gwake; Saũlũ na mũriũ Jonathani no-o maarĩ nacio.
Bẹ́ẹ̀ ni ọjọ́ ìjà ẹnìkankan nínú àwọn ọmọ-ogun tí ó wà pẹ̀lú Saulu àti Jonatani kò sì ní idà, tàbí ọ̀kọ̀ ní ọwọ́; àfi Saulu àti ọmọ rẹ̀ Jonatani ni wọ́n ni wọ́n.
23 Na rĩrĩ, gĩkundi gĩa thigari cia Afilisti nĩgĩathiĩte nginya kĩhunguro-inĩ kũu Mikimashi.
Àwọn ẹgbẹ́ ogun Filistini sì ti jáde lọ sí ìkọjá Mikmasi.

< 1 Samũeli 13 >