< 1 Samũeli 12 >
1 Na rĩrĩ, Samũeli akĩĩra andũ a Isiraeli othe atĩrĩ, “Nĩndĩkĩtie gũthikĩrĩria ũrĩa wothe mwanjĩĩrire, na nĩndĩmũthuurĩire mũthamaki wa kũmũthamakagĩra.
Samuẹli sì wí fún gbogbo Israẹli pé, “Èmi tí gbọ́ gbogbo ohun tí ẹ sọ fún mi, èmi sì ti yan ọba fún un yín.
2 Rĩu mũrĩ na mũthamaki wa kũmũtongoria. Hakwa-rĩ, ndĩ mũkũrũ na ngagĩa na mbuĩ, nao ariũ akwa me hamwe na inyuĩ. Ngoretwo ndĩ mũtongoria wanyu kuuma ndĩ mwĩthĩ nginya ũmũthĩ.
Nísinsin yìí ẹ ti ní ọba bí olórí yín. Bí ó ṣe tèmi, èmi ti di arúgbó, mo sì ti hewú, àwọn ọmọ mi sì ń bẹ níhìn-ín yìí pẹ̀lú yín. Èmi ti ń ṣe olórí yín láti ìgbà èwe mi wá títí di òní yìí.
3 Niĩ nũngiĩ haha. Rutai ũira wa kũnyuna mũtĩ mũrĩ mbere ya Jehova, na mũrĩ mbere ya mũndũ ũyũ wake ũitĩrĩirio maguta. Nũũ ndaanatunya ndegwa yake? Nũũ ndaanatunya ndigiri yake? Nũũ ndaanaheenia? Nũũ ndaanahinyĩrĩria? Nĩ kũrĩ mũndũ o na ũ ndĩ ndaamũkĩra ihaki nĩguo nyune maitho nĩ ũndũ warĩo? Kũngĩkorwo ndaneeka ũmwe wa maya-rĩ, nĩngũmũcookeria.”
Èmi dúró níhìn-ín yìí, ẹ jẹ́rìí sí mi níwájú Olúwa àti níwájú ẹni àmì òróró rẹ̀. Màlúù ta ni mo gbà rí? Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ta ni mo gbà rí? Ta ni mo rẹ́ jẹ rí? Ọwọ́ ta ni mo ti gba owó àbẹ̀tẹ́lẹ̀ kan rí láti fi bo ara mi lójú? Bí mo bá ti ṣe nǹkan kan nínú ohun wọ̀nyí, èmi yóò sì san án padà fún yín.”
4 Nao magĩcookia atĩrĩ, “Ndũrĩ watũheenia kana ũgĩtũhinyĩrĩria; ndũrĩ woya kĩndũ kuuma guoko-inĩ kwa mũndũ o na ũrĩkũ.”
Wọ́n sì dáhùn wí pé, “Ìwọ kò rẹ́ wa jẹ tàbí pọ́n wa lójú rí, ìwọ kò sì gba ohunkóhun lọ́wọ́ ẹnìkankan.”
5 Samũeli akĩmeera atĩrĩ, “Jehova nĩwe mũira ũhoro-inĩ wanyu, o na mũndũ ũyũ aitĩrĩirie maguta nĩ mũira ũmũthĩ, atĩ gũtirĩ ũndũ o na ũmwe mũngĩnjuukĩra.” Nao makiuga atĩrĩ, “Ĩĩ we nĩ mũira.”
Samuẹli sì wí fún wọn pé, “Olúwa ni ẹlẹ́rìí sí i yín, àti ẹni àmì òróró rẹ̀ ni ẹlẹ́rìí lónìí pé, ẹ̀yin kò rí ohunkóhun lọ́wọ́ mi.” Wọ́n sì sọ wí pé, “Òun ni ẹlẹ́rìí.”
6 Samũeli agĩcooka akĩĩra andũ atĩrĩ, “Jehova nĩwe waamũrire Musa na Harũni, na akĩambatia maithe manyu ma tene kuuma bũrũri wa Misiri.
Nígbà náà ni Samuẹli wí fún àwọn ènìyàn náà pé, “Olúwa ni ó yan Mose àti Aaroni àti ti ó mú àwọn baba ńlá yín gòkè wá láti Ejibiti.
7 Na rĩrĩ, ta rũgamai haha, tondũ nĩngũmũciirithia na ũira mbere ya Jehova nĩ ũndũ wa maũndũ ma ũthingu marĩa Jehova anamwĩkĩra inyuĩ ene o na maithe manyu.
Nísinsin yìí, ẹ dúró níbi, nítorí èmi ń lọ láti bá a yín sọ̀rọ̀ níwájú Olúwa ní ti gbogbo ìṣe òdodo rẹ̀ tí ó ti ṣe fún un yín àti fún àwọn baba yín.
8 “Rĩrĩa ciana cia Jakubu ciathiire Misiri, nĩmakaĩire Jehova amateithie, nake Jehova agĩtũma Musa na Harũni arĩa maarutire maithe manyu ma tene kuuma bũrũri wa Misiri, makĩmathaamĩria kũndũ gũkũ.
“Lẹ́yìn ìgbà tí Jakọbu wọ Ejibiti, wọ́n ké pe Olúwa fún ìrànlọ́wọ́, Olúwa sì rán Mose àti Aaroni, tí wọ́n mú àwọn baba ńlá yín jáde láti Ejibiti láti mú wọn jókòó níbí yìí.
9 “No nĩmariganĩirwo nĩ Jehova Ngai wao; nĩ ũndũ ũcio nĩameendirie guoko-inĩ gwa Sisera, mũnene wa mbũtũ cia ita cia Hazoru, na moko-inĩ ma Afilisti, na mũthamaki wa Moabi ũrĩa warũire nao.
“Ṣùgbọ́n wọ́n gbàgbé Olúwa Ọlọ́run wọn; bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì tà wọ́n sí ọwọ́ àwọn Sisera, olórí ogun Hasori, àti sí ọwọ́ àwọn Filistini àti sí ọwọ́ ọba Moabu, tí ó bá wọn jà.
10 Nao magĩkaĩra Jehova makiuga atĩrĩ, ‘Nĩtwĩhĩtie; nĩtũtiganĩirie Jehova tũgatungatĩra Mabaali na Maashitarothu. No rĩu gĩtũhonokie kuuma moko-inĩ ma thũ ciitũ, na nĩtũrĩgũtungatagĩra.’
Wọ́n kégbe pe Olúwa, wọ́n sì wí pé, ‘Àwa ti ṣẹ̀; a ti kọ Olúwa sílẹ̀, a sì ti sin Baali, àti Aṣtoreti. Ṣùgbọ́n nísinsin yìí gbà wá lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa, àwa yóò sì sìn ọ́.’
11 Jehova agĩcooka agĩtũma Jerubu-Baali, na Baraka, na Jefitha, na Samũeli, na akĩmũhonokia kuuma moko-inĩ ma thũ cianyu mĩena-inĩ yothe; nĩ ũndũ ũcio mũgĩtũũra mũtarĩ na ũgwati.
Nígbà náà ni Olúwa rán Jerubbaali, Bedani, Jefta àti Samuẹli, ó sì gbà yín lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá a yín gbogbo, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin ń gbé ní àlàáfíà.
12 “No hĩndĩ ĩrĩa muonire atĩ Nahashu mũthamaki wa Amoni nĩookaga kũmũhũũra-rĩ, mũkĩnjĩĩra atĩrĩ, ‘Aca, tũkwenda mũthamaki wa gũtũthamakagĩra,’ o na gwatuĩka atĩ Jehova Ngai wanyu nĩwe warĩ mũthamaki wanyu.
“Ṣùgbọ́n nígbà tí ẹ̀yin sì rí i pé Nahaṣi ọba àwọn Ammoni dìde sí i yín, ẹ sọ fún mi pé, ‘Rárá, àwa ń fẹ́ ọba tí yóò jẹ́ lórí wa,’ bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé Olúwa Ọlọ́run yín jẹ́ ọba yín.
13 Rĩu ũyũ nĩwe mũthamaki ũrĩa mũthuurĩte, o ũrĩa mwetirie; onei, Jehova nĩarũgamĩtie mũthamaki amũthamakagĩre.
Nísinsin yìí èyí ni ọba tí ẹ̀yin ti yàn, tí ẹ̀yin béèrè fún; wò ó, Olúwa ti fi ọba jẹ lórí yín.
14 Mũngĩĩtigĩra Jehova, mũmũtungatĩre, na mũmwathĩkĩre, na mũtikaremere maathani make, na angĩkorwo inyuĩ na mũthamaki ũrĩa ũkũmũthamakĩra nĩmũrĩrũmagĩrĩra Jehova Ngai wanyu-rĩ, nĩ wega!
Bí ẹ̀yin bá bẹ̀rù Olúwa àti bí ẹ̀yin bá ń sìn ín, tí ẹ sì gbọ́ tirẹ̀, tí ẹ̀yin kò sì ṣọ̀tẹ̀ sí àṣẹ rẹ̀, àti tí ẹ̀yin àti ọba tí ó jẹ lórí yín bá ń tẹ̀lé Olúwa Ọlọ́run yín: ó dára
15 No mũngĩaga gwathĩkĩra Jehova, na mũremere maathani make-rĩ, guoko gwake nĩgũkamũũkĩrĩra ta ũrĩa guokĩrĩire maithe manyu.
ṣùgbọ́n bí ẹ̀yin kò bá gbọ́ tí Olúwa, tí ẹ sì ṣọ̀tẹ̀ sí àṣẹ rẹ̀, ọwọ́ rẹ̀ yóò wà lára yín sí ibi, bí ó ti wà lára baba yín.
16 “Na rĩrĩ, rũgamai muone ũndũ ũyũ mũnene Jehova akiriĩ gwĩka maitho-inĩ manyu!
“Nítorí náà, ẹ dúró jẹ́ẹ́ kí ẹ sì wo ohun ńlá yìí tí Olúwa fẹ́ ṣe ní ojú u yín!
17 Githĩ rĩu ti hĩndĩ ya magetha ma ngano? Nĩngũkaĩra Jehova atũme marurumĩ na mbura. Na inyuĩ nĩmũkamenya atĩ nĩ ũndũ mũũru mwekire maitho-inĩ ma Jehova rĩrĩa mwetirie mũthamaki.”
Òní kì í ha á ṣe ọjọ́ ìkórè ọkà alikama bí? Èmi yóò ké pe Olúwa kí ó rán àrá àti òjò. Ẹ̀yin yóò sì mọ irú ohun búburú tí ẹ ti ṣe níwájú Olúwa nígbà tí ẹ̀ ń béèrè fún ọba.”
18 Ningĩ Samũeli agĩkaĩra Jehova, na mũthenya o ro ũcio Jehova agĩtũma marurumĩ na mbura. Nĩ ũndũ ũcio andũ othe makĩmaka mũno nĩ ũndũ wa Jehova na wa Samũeli.
Nígbà náà ni Samuẹli ké pe Olúwa, Olúwa sì rán àrá àti òjò ní ọjọ́ náà. Bẹ́ẹ̀ ni gbogbo ènìyàn sì bẹ̀rù Olúwa àti Samuẹli púpọ̀.
19 Nao andũ acio othe makĩĩra Samũeli atĩrĩ, “Hooya Jehova Ngai waku nĩ ũndũ wa ndungata ciaku nĩguo tũtigakue, nĩgũkorwo igũrũ rĩa mehia maitũ mothe nĩtuongereire ũũru wa gwĩtia mũthamaki.”
Gbogbo àwọn ènìyàn sì wí fún Samuẹli pé, “Gbàdúrà sí Olúwa Ọlọ́run rẹ fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ kí a má ba à kú, nítorí tí àwa ti fi búburú yìí kún ẹ̀ṣẹ̀ wa ní bíbéèrè fún ọba.”
20 Samũeli agĩcookia atĩrĩ, “Tigai gwĩtigĩra, inyuĩ nĩmwĩkĩte ũũru ũyũ wothe; no rĩrĩ, mũtikanahutatĩre Jehova, no tungatĩrai Jehova na ngoro cianyu ciothe.
Samuẹli sì dá wọn lóhùn pé, “Ẹ má bẹ̀rù, ẹ ti ṣe gbogbo búburú yìí; síbẹ̀ ẹ má ṣe yípadà kúrò lọ́dọ̀ Olúwa, ṣùgbọ́n ẹ fi gbogbo àyà yín sin Olúwa.
21 Mũtikanagarũrũkĩre mĩhianano ya kũhooywo ya tũhũ. Ndĩngĩmũguna, o na ndĩngĩmũhonokia, nĩ ũndũ nĩ ya tũhũ.
Ẹ má ṣe yípadà sọ́dọ̀ àwọn òrìṣà. Wọn kò le ṣe ohun rere kan fún un yín, tàbí kí wọ́n gbà yín là, nítorí asán ni wọ́n.
22 Nĩ ũndũ wa rĩĩtwa rĩake inene, Jehova ndagatirika andũ ake, nĩ ũndũ Jehova nĩakenirio nĩ kũmũtua andũ ake.
Nítorí orúkọ ńlá rẹ̀ Olúwa kì yóò kọ àwọn ènìyàn rẹ̀ sílẹ̀, nítorí tí inú Olúwa dùn láti fi yín ṣe ènìyàn rẹ̀.
23 No hakwa niĩ mwene-rĩ, ndĩroaga kwĩhĩria Jehova nĩ ũndũ wa kwaga kũmũhoera. Na nĩngũmũruta njĩra ĩrĩa njega na njagĩrĩru.
Bí ó ṣe ti èmi ni, kí á má rí i pé èmi dẹ́ṣẹ̀ sí Olúwa nípa dídẹ́kun àti gbàdúrà fún un yín. Èmi yóò sì kọ́ ọ yín ní ọ̀nà rere àti ọ̀nà òtítọ́.
24 No mwĩtigagĩrei Jehova na mũmũtungatagĩre mũrĩ na wĩhokeku ngoro-inĩ cianyu ciothe; cũraniai maũndũ manene marĩa amwĩkĩire.
Ṣùgbọ́n ẹ rí i dájú pé, ẹ bẹ̀rù Olúwa, kí ẹ sì sìn ín nínú òtítọ́ pẹ̀lú gbogbo ọkàn an yín, ẹ kíyèsi ohun ńlá tí ó ti ṣe fún un yín.
25 No mũngĩkorwo nĩmũkũrũmanĩrĩria gwĩkaga ũũru-rĩ, inyuĩ hamwe na mũthamaki wanyu nĩmũkaniinwo biũ.”
Síbẹ̀ bí ẹ̀yin bá ń ṣe búburú, ẹ̀yin àti ọba yín ni a ó gbá kúrò.”