< 1 Athamaki 21 >

1 Na rĩrĩ, thuutha ũcio gũkĩgĩa na ũndũ wakoniĩ mũgũnda wa mĩthabibũ wa Nabothu ũrĩa Mũjezireeli. Mũgũnda ũcio wa mĩthabibũ warĩ kũu Jezireeli, hakuhĩ na nyũmba ya ũthamaki ya Ahabu mũthamaki wa Samaria.
Ó sì ṣe lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí Naboti ará Jesreeli sì ní ọgbà àjàrà kan ní Jesreeli, ní ẹ̀gbẹ́ ààfin Ahabu ọba Samaria.
2 Nake Ahabu akĩĩra Nabothu atĩrĩ, “He mũgũnda waku wa mĩthabibũ haandage mboga, tondũ ũrĩ hakuhĩ na nyũmba yakwa ya ũthamaki. Nĩngũgũkũũranĩria na mũgũnda ũngĩ wa mĩthabibũ mwega gũkĩra ũyũ, kana ũngĩona arĩ wega, no ngũhe mbeeca ciiganĩte thogora waguo.”
Ahabu sì wí fún Naboti pé, “Fún mi ní ọgbà àjàrà rẹ, kí èmi kí ó fi ṣe ọgbà-ewébẹ̀, nítorí tí ó súnmọ́ tòsí ilé mi, èmi yóò sì fún ọ ní ọgbà àjàrà tí ó sàn jù ú lọ dípò rẹ̀; tàbí bí ó bá sì dára ní ojú rẹ, èmi yóò fi iye owó rẹ̀ fún ọ.”
3 No Nabothu akĩmũcookeria atĩrĩ, “Jehova arogiria ngũhe igai rĩa maithe makwa.”
Ṣùgbọ́n Naboti wí fún Ahabu pé, “Olúwa má jẹ́ kí èmi fi ogún àwọn baba mi fún ọ.”
4 Nĩ ũndũ ũcio Ahabu akĩinũka athitĩtie gĩthiithi na arĩ mũrakaru, tondũ Nabothu ũrĩa Mũjezireeli nĩamwĩrire atĩrĩ, “Ndingĩkũhe igai rĩa maithe makwa.” Agĩkoma ũrĩrĩ wake angʼathĩtie na akĩrega kũrĩa irio.
Ahabu sì wá sí ilé rẹ̀, ó wugbọ́, inú rẹ̀ sì bàjẹ́ nítorí ọ̀rọ̀ tí Naboti ará Jesreeli sọ fún un; nítorí tí ó wí pé, “Èmi kì yóò fún ọ ní ogún àwọn baba mi.” Ó sì dùbúlẹ̀ lórí ibùsùn rẹ̀, ó sì yí ojú rẹ̀ padà, kò sì fẹ́ jẹun.
5 Nake Jezebeli mũtumia wake akĩingĩra akĩmũũria atĩrĩ, “Nĩ kĩĩ gĩtũmĩte ũtukie gĩthiithi? Ũrarega kũrĩa irio nĩkĩ?”
Jesebeli aya rẹ̀ sì tọ̀ ọ́ wá, ó sì béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Èéṣe tí inú rẹ fi bàjẹ́, èéṣe tí ìwọ kò sì jẹun?”
6 Nake akĩmũcookeria atĩrĩ, “Nĩ tondũ njĩĩrire Nabothu ũrĩa Mũjezireeli atĩrĩ, ‘Nyenderia mũgũnda waku wa mĩthabibũ, kana ũngĩona kwagĩrĩire, ngũhe mũgũnda ũngĩ wa mĩthabibũ handũ haguo.’ No anjĩĩra atĩrĩ, ‘Ndingĩkũhe mũgũnda wakwa wa mĩthabibũ.’”
Ó sì dá a lóhùn pé, “Nítorí tí mo wí fún Naboti ará Jesreeli pé, ‘Ta ọgbà àjàrà rẹ fún mi, tàbí bí ó bá wù ọ́, èmi yóò fún ọ ní ọgbà àjàrà mìíràn ní ipò rẹ̀.’ Ṣùgbọ́n ó wí pé, ‘Èmi kì yóò fún ọ ní ọgbà àjàrà mi.’”
7 Jezebeli mũtumia wake akĩmwĩra atĩrĩ, “Ũguo nĩguo ũgwĩka arĩ we mũthamaki wa Isiraeli? Ũkĩra ũrĩe! Kena. Nĩ niĩ ngũkũhe mũgũnda wa mĩthabibũ wa Nabothu ũcio Mũjezireeli.”
Jesebeli aya rẹ̀ sì wí pé, “Ṣé báyìí ni ìwọ yóò ṣe ṣe bí ọba lórí Israẹli? Dìde, jẹun! Kí o sì jẹ́ kí inú rẹ̀ dùn. Èmi yóò sì fún ọ ní ọgbà àjàrà Naboti ará Jesreeli.”
8 Nĩ ũndũ ũcio akĩandĩka marũa na rĩĩtwa rĩa Ahabu, na akĩmahũũra mũhũũri wake, akĩmatũma kũrĩ athuuri na anene arĩa maatũũranagia na Nabothu itũũra-inĩ rĩake inene.
Bẹ́ẹ̀ ni ó kọ̀wé ní orúkọ Ahabu, ó sì fi èdìdì rẹ̀ dì í, ó sì fi ìwé náà ránṣẹ́ sí àwọn àgbàgbà àti àwọn ọlọ́lá tí ó ń gbé ní ìlú Naboti pẹ̀lú rẹ̀.
9 Marũa-inĩ macio aandĩkĩte ũũ: “Anĩrĩrai mũthenya wa kwĩhinga kũrĩa irio, na mũikarĩrie Nabothu handũ ekuoneka, gatagatĩ ka andũ.
Nínú àwọn ìwé náà, ó kọ pé, “Ẹ kéde àwẹ̀, kí ẹ sì fi Naboti sí ipò ọlá láàrín àwọn ènìyàn.
10 No mũige imaramari igĩrĩ imũngʼetheire, mũciĩre irute ũira wa atĩ nĩarumĩte Ngai na akaruma mũthamaki. Mũcooke mũmuumie nja ya itũũra mũmũhũre na mahiga nyuguto nginya akue.”
Ṣùgbọ́n kí ẹ fi ènìyàn méjì, ẹni búburú síwájú rẹ̀ láti jẹ́rìí sí i wí pé, ó bú Ọlọ́run àti ọba. Nígbà náà ni kí ẹ mú u jáde, kí ẹ sì sọ ọ́ ní òkúta pa.”
11 Nĩ ũndũ ũcio athuuri na anene arĩa maatũũraga itũũra-inĩ inene rĩa Nabothu magĩĩka o ta ũrĩa Jezebeli aathanĩte marũa-inĩ macio aamaandĩkĩire.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn àgbàgbà àti àwọn ọlọ́lá tí wọ́n ń ṣe ará ìlú Naboti sì ṣe gẹ́gẹ́ bí ìwé tí Jesebeli kọ ránṣẹ́ sí wọn.
12 Makĩanĩrĩra mũthenya wa kwĩhinga kũrĩa irio, na magĩikarĩria Nabothu handũ ekuoneka, gatagatĩ-inĩ ka andũ.
Wọ́n sì kéde àwẹ̀, wọ́n sì fi Naboti sí ipò ọlá láàrín àwọn ènìyàn.
13 Ningĩ imaramari igĩrĩ igĩikara imũngʼetheire, na ikĩruta thitango ya gũũkĩrĩra Nabothu mbere ya andũ, ikiuga atĩrĩ, “Nabothu nĩarumĩte Ngai, na akaruma mũthamaki.” Nĩ ũndũ ũcio makĩmuumia nja ya itũũra inene, makĩmũhũũra na mahiga nyuguto nginya agĩkua.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọkùnrin méjì sì dé, àwọn ẹni búburú, wọ́n sì jókòó síwájú rẹ̀, wọ́n sì jẹ́rìí lòdì sí Naboti níwájú àwọn ènìyàn wí pé, “Naboti ti bú Ọlọ́run àti ọba.” Nígbà náà ni wọ́n mú jáde kúrò ní ìlú, wọ́n sì sọ ọ́ ní òkúta pa.
14 Magĩcooka magĩtwara ũhoro kũrĩ Jezebeli, makĩmwĩra atĩrĩ, “Nabothu nĩmũhũũre na mahiga nyuguto na nĩ mũkuũ.”
Nígbà náà ni wọ́n ránṣẹ́ sí Jesebeli wí pé, “A ti sọ Naboti ní òkúta, ó sì kú.”
15 Jezebeli aarĩkia kũigua atĩ Nabothu nĩahũrĩtwo na mahiga nyuguto agakua-rĩ, akĩĩra Ahabu atĩrĩ “Ũkĩra wĩgwatĩre mũgũnda wa mĩthabibũ wa Nabothu ũrĩa Mũjezireeli ũcio araregete gũkwenderia. Ndarĩ muoyo, nĩakuĩte.”
Bí Jesebeli sì ti gbọ́ pé, a ti sọ Naboti ní Òkúta pa, ó sì wí fún Ahabu pé, “Dìde! Kí o sì jogún ọgbà àjàrà Naboti, ará Jesreeli, tí ó kọ̀ láti tà fún ọ kò sí láààyè mọ́, ó ti kú.”
16 Hĩndĩ ĩrĩa Ahabu aiguire atĩ Nabothu nĩakuĩte, agĩũkĩra, agĩikũrũka akegwatĩre mũgũnda wa mĩthabibũ wa Nabothu.
Nígbà tí Ahabu sì gbọ́ pé Naboti ti kú, ó sì dìde, ó sì sọ̀kalẹ̀ lọ láti jogún ọgbà àjàrà Naboti.
17 Na rĩrĩ, kiugo kĩa Jehova gĩgĩkinyĩra Elija ũrĩa Mũtishibi akĩĩrwo atĩrĩ,
Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Elijah ará Tiṣibi wá wí pé,
18 “Ikũrũka ũgatũnge Ahabu mũthamaki wa Isiraeli, ũrĩa wathanaga Samaria. Rĩu arĩ mũgũnda-inĩ wa mĩthabibũ wa Nabothu kũrĩa athiĩte kwĩgwatĩra mũgũnda ũcio ũtuĩke wake.
“Sọ̀kalẹ̀ lọ láti lọ pàdé Ahabu ọba Israẹli, tí ó wà ní Samaria. Ó wà ní ọgbà àjàrà Naboti báyìí, níbi tí ó sọ̀kalẹ̀ lọ láti jogún rẹ̀.
19 Mwĩre atĩrĩ, ‘Jehova ekuuga ũũ: Githĩ ndũũragĩte mũndũ na ũkaamũtunya indo ciake?’ Ningĩ ũmwĩre atĩrĩ, ‘Jehova ekuuga ũũ: Handũ harĩa ngui iracũnĩire thakame ya Nabothu-rĩ, hau no ho ngui igaacũnĩra thakame yaku, ĩĩ, yaku wee mwene!’”
Sọ fún un pé, ‘Báyìí ni Olúwa wí: Ǹjẹ́ ìwọ kò ti pa ènìyàn, o sì ti fi agbára gba ogún rẹ̀?’ Nígbà náà ni kí o wí fún un pé, ‘Báyìí ni Olúwa wí: Níbi tí ajá gbé lá ẹ̀jẹ̀ Naboti, ni àwọn ajá yóò lá ẹ̀jẹ̀ rẹ, àní tìrẹ!’”
20 Nake Ahabu akĩĩra Elija atĩrĩ, “Wee thũ yakwa, anga nĩwangora!” Nake Elija agĩcookia atĩrĩ, “Ĩĩ, nĩndagũkora, tondũ nĩwĩrutĩire gwĩka ũũru maitho-inĩ ma Jehova.
Ahabu sì wí fún Elijah pé, “Ìwọ ti rí mi, ìwọ ọ̀tá mi!” Ó sì dáhùn wí pé, “Èmi ti rí ọ, nítorí tí ìwọ ti tan ara rẹ láti ṣe búburú níwájú Olúwa.
21 ‘Na rĩrĩ, nĩngũkũrehere mwanangĩko. Nĩngũniina njiaro ciaku, na niinĩre Ahabu ciana ciothe cia arũme thĩinĩ wa Isiraeli, arĩ ngombo kana ũrĩa ũtarĩ ngombo.
‘Èmi yóò mú ibi wá sórí rẹ. Èmi yóò sì mú ìran rẹ kúrò, èmi yóò sì ké kúrò lọ́dọ̀ Ahabu gbogbo ọmọdé ọkùnrin, àti ọmọ ọ̀dọ̀, àti òmìnira ní Israẹli.
22 Nĩngatũma nyũmba yaku ĩhaane o ta ya Jeroboamu mũrũ wa Nebati, na ta ya Baasha mũrũ wa Ahija, tondũ nĩũndakarĩtie na ũgatũma Isiraeli mehie.’
Èmi yóò ṣe ilé rẹ bí ilé Jeroboamu, ọmọ Nebati, àti bí ilé Baaṣa, ọmọ Ahijah, nítorí ìwọ ti mú mi bínú, ìwọ sì ti mú Israẹli ṣẹ̀.’
23 “Naguo ũhoro ũkoniĩ Jezebeli, Jehova ekuuga ũũ: ‘Ngui nĩigatambuurangĩra Jezebeli rũthingo-inĩ rwa Jezireeli.’
“Àti ní ti Jesebeli pẹ̀lú Olúwa wí pé, ‘Àwọn ajá yóò jẹ Jesebeli nínú yàrá Jesreeli.’
24 “Andũ a Ahabu arĩa magaakuĩra itũũra-inĩ, makaarĩĩo nĩ ngui. Nao arĩa magaakuĩra mĩgũnda-inĩ makaarĩĩo nĩ nyoni cia rĩera-inĩ.”
“Àwọn ajá yóò jẹ ẹni Ahabu tí ó kú ní ìlú, àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run yóò jẹ àwọn ẹni tí ó kú ní igbó.”
25 (Na rĩrĩ, gũtirĩ kuoneka mũndũ ta Ahabu werutĩire gwĩka ũũru maitho-inĩ ma Jehova, aringĩrĩirio nĩ mũtumia wake Jezebeli.
(Kò sí ẹnìkan bí Ahabu tí ó ta ara rẹ̀ láti ṣe búburú níwájú Olúwa, ẹni tí Jesebeli aya rẹ̀ ń tì.
26 Mĩtugo yake yarĩ mĩũru mũno nĩ ũndũ wa kũrũmĩrĩra mĩhianano ya kũhooywo ta ũrĩa Aamori meekaga, arĩa Jehova aingatire akĩmeheria mbere ya Isiraeli.)
Ó sì ṣe ohun ìríra gidigidi ní tí tọ òrìṣà lẹ́yìn, gẹ́gẹ́ bí gbogbo ohun tí àwọn ará Amori ti ṣe, tí Olúwa lé jáde níwájú àwọn ọmọ Israẹli.)
27 Hĩndĩ ĩrĩa Ahabu aiguire ciugo icio, agĩtarũranga nguo ciake, akĩĩhumba nguo ya ikũnia na akĩĩhinga kũrĩa irio. Aakomaga ehumbĩte nguo ya ikũnia na agathiiaga enyiihĩtie.
Nígbà tí Ahabu sì gbọ́ àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí, ó sì fa aṣọ rẹ̀ ya, ó sì fi aṣọ ọ̀fọ̀ sí ara rẹ̀, ó sì gbààwẹ̀. Ó sì dùbúlẹ̀ nínú aṣọ ọ̀fọ̀, ó sì ń lọ jẹ́ẹ́.
28 Hĩndĩ ĩyo kiugo kĩa Jehova gĩgĩkinyĩra Elija ũrĩa Mũtishibi, akĩũrio atĩrĩ:
Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Elijah ará Tiṣibi wá wí pé,
29 “Nĩwonete ũrĩa Ahabu enyiihĩtie mbere yakwa? Tondũ we nĩenyiihĩtie, ndikarehe mwanangĩko ũyũ matukũ-inĩ make, no nĩngaũrehere nyũmba yake matukũ-inĩ ma mũriũ.”
“Ǹjẹ́ ìwọ ti rí bí Ahabu ti rẹ̀ ara rẹ̀ sílẹ̀ níwájú mi? Nítorí tí ó ti rẹ̀ ara rẹ̀ sílẹ̀, èmi kì yóò mú ibi náà wá ní ọjọ́ rẹ, ṣùgbọ́n èmi yóò mú u wá sí ilé rẹ̀ ní ọjọ́ ọmọ rẹ̀.”

< 1 Athamaki 21 >