< 1 Maũndũ 21 >

1 Na rĩrĩ, Shaitani nĩookĩrĩire andũ a Isiraeli, na akĩarahũra Daudi nĩguo atarithie andũ a Isiraeli.
Satani sì dúró ti Israẹli, ó sì ti Dafidi láti ka iye Israẹli.
2 Nĩ ũndũ ũcio Daudi akĩĩra Joabu na anene a mbũtũ cia ita atĩrĩ: “Thiĩi mũgatare andũ a Isiraeli kuuma Birishiba nginya Dani, mũcooke mũndehere ũhoro nĩguo menye ũrĩa maigana.”
Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi sì wí fún Joabu àti àwọn olórí àwọn ènìyàn pé, “Lọ kí o ka iye àwọn ọmọ Israẹli láti Beerṣeba títí dé Dani. Kí o sì padà mú iye wọn fún mi wa, kí èmi kí ó le mọ iye tí wọ́n jẹ́.”
3 Nowe Joabu akĩmũcookeria atĩrĩ, “Jehova aroingĩhia mbũtũ ciake cia ita maita igana. Mwathi wakwa mũthamaki, githĩ othe matirĩ watho-inĩ waku? Nĩ kĩĩ gĩgũtũma mwathi wakwa ende gwĩka ũguo? Nĩ kĩĩ gĩgũtũma ahĩtithie Isiraeli?”
Ṣùgbọ́n Joabu dá a lóhùn pé, “Kí Olúwa kí ó mú àwọn ènìyàn rẹ̀ pọ̀ sí ní ìgbà ọgọ́rùn-ún ju ti tẹ́lẹ̀ lọ, ọba olúwa mi, gbogbo wọn kì í ha ṣe ìránṣẹ́ olúwa ni? Kí ni ó dé tí olúwa mi ṣe fẹ́ ṣè yìí? Kí ni ó de tí yóò fi mú ẹ̀bi wá sórí Israẹli?”
4 No rĩrĩ, mũthamaki agĩkararia Joabu; nĩ ũndũ ũcio Joabu akiuma hau agĩthiĩ Isiraeli guothe, na agĩcooka Jerusalemu.
Ṣùgbọ́n ọ̀rọ̀ ọba borí tí Joabu. Bẹ́ẹ̀ ni Joabu jáde lọ, ó sì la gbogbo Israẹli já, ó sí dé Jerusalẹmu.
5 Joabu akĩmenyithia Daudi mũigana wa andũ arĩa maangĩarũire mbaara ta ũũ: Isiraeli guothe kwarĩ na andũ 1,100,000 arĩa maangĩahotire kũhũthĩra rũhiũ rwa njora, thĩinĩ wao haarĩ na andũ 470,000 kuuma Juda.
Joabu sì fi àpapọ̀ iye àwọn ènìyàn náà fún Dafidi. Ní gbogbo Israẹli, ó sì jẹ́ ẹgbẹ̀rún ẹgbẹ̀rún àti ọ̀kẹ́ márùn-ún ènìyàn tí ń kọ́ idà, Juda sì jẹ́ ọ̀kẹ́ mẹ́tàlélógún lé ẹgbàárùn-ún ọkùnrin tí ń kọ́ idà.
6 No rĩrĩ, Joabu ndaatarire andũ a Lawi na a Benjamini, tondũ watho ũcio wa mũthamaki nĩwamũiguithĩtie ũũru mũno.
Ṣùgbọ́n Joabu kó àwọn Lefi àti Benjamini mọ́ iye wọn, nítorí àṣẹ ọba jẹ́ ìríra fún un.
7 O na ningĩ watho ũcio warĩ mũũru maitho-inĩ ma Ngai; nĩ ũndũ ũcio akĩherithia Isiraeli.
Àṣẹ yìí pẹ̀lú sì jẹ́ búburú lójú Ọlọ́run, bẹ́ẹ̀ ni ó sì díyàjẹ Israẹli.
8 Hĩndĩ ĩyo Daudi akĩĩra Ngai atĩrĩ, “Nĩnjĩhĩtie mũno nĩ gwĩka ũndũ ũyũ. Rĩu ndagũthaitha ũnjehererie mahĩtia, niĩ ndungata yaku. Nĩnjĩkĩte ũndũ wa ũrimũ mũno.”
Nígbà náà Dafidi sọ fún Ọlọ́run pé, èmi ti dẹ́ṣẹ̀ gidigidi nípa ṣíṣe èyí. Nísinsin yìí, èmi bẹ̀ ọ́, mú ìjẹ̀bi àwọn ìránṣẹ́ rẹ kúrò. Èmi ti hùwà aṣiwèrè gidigidi.
9 Nake Jehova akĩĩra Gadi ũrĩa woonagĩra Daudi maũndũ atĩrĩ,
Olúwa sì fi fún Gadi, aríran Dafidi pé.
10 “Thiĩ ũkeere Daudi ũũ, ‘Jehova ekuuga atĩrĩ: Ũrĩ na maũndũ matatũ ma gũthuura. Nowe ũthuure ũmwe wamo ũrĩa ngũkũherithia naguo.’”
“Lọ kí o sì wí fún Dafidi pé, ‘Báyìí ni Olúwa wí, èmi fi nǹkan mẹ́ta lọ̀ ọ́; yan ọ̀kan nínú wọn, kí èmi ó sì ṣe é sí ọ.’”
11 Nĩ ũndũ ũcio Gadi agĩthiĩ kũrĩ Daudi, akĩmwĩra atĩrĩ, “Jehova ekuuga ũũ: ‘Thuura ũndũ ũmwe wa maya:
Bẹ́ẹ̀ ni Gadi tọ Dafidi wá, ó sì wí fún un pé, “Báyìí ni Olúwa wí: ‘Yan fún ara rẹ.
12 Ũthuure mĩaka ĩtatũ ya ngʼaragu, kana mĩeri ĩtatũ ya kũniinwo nĩ thũ ciaku igũthingatĩte na hiũ ciao cia njora, kana mĩthenya ĩtatũ ya rũhiũ rwa njora rwa Jehova, naguo nĩ atĩ kũgĩe na mĩthenya ya mũthiro bũrũri-inĩ, rĩrĩa mũraika wa Jehova akaaniinana Isiraeli guothe.’ Na rĩrĩ, tua itua ũnjĩĩre ũrĩa ngũthiĩ gũcookeria ũrĩa ũndũmĩte.”
Ọdún mẹ́ta ìyàn, tàbí ìparun ní oṣù mẹ́ta níwájú àwọn ọ̀tá rẹ, pẹ̀lú idà wọn láti lé ọ bá, tàbí ọjọ́ mẹ́ta idà Olúwa ọjọ́ àjàkálẹ̀-ààrùn ní ilẹ̀ náà, pẹ̀lú àwọn angẹli Olúwa láti pa gbogbo agbègbè Israẹli run.’ Nísinsin yìí ǹjẹ́, rò ó wò, èsì wo ni èmi yóò mú padà tọ ẹni tí ó rán mi.”
13 Daudi akĩĩra Gadi atĩrĩ, “Rĩu niĩ ndĩ na thĩĩna mũno. Nĩ kaba niĩ ngwe moko-inĩ ma Jehova, tondũ tha ciake nĩ nyingĩ mũno; no ndũkareke ngwe moko-inĩ ma andũ.”
Dafidi sì wí fún Gadi pé, “Ìyọnu ńlá bá mi. Jẹ́ kí èmi kí ó ṣubú sí ọwọ́ Olúwa nísinsin yìí, nítorí tí àánú rẹ̀ pọ̀ gidigidi, ṣùgbọ́n má ṣe jẹ́ kí èmi kí o ṣubú sí ọwọ́ àwọn ènìyàn.”
14 Nĩ ũndũ ũcio Jehova akĩrehera Isiraeli mũthiro, na andũ a Isiraeli 70,000 magĩkua.
Bẹ́ẹ̀ ni Olúwa rán àjàkálẹ̀-ààrùn lórí Israẹli, àwọn tí ó ṣubú ní Israẹli jẹ́ ẹgbẹ̀rún ní ọ̀nà àádọ́rin ènìyàn.
15 Nake Ngai agĩtũma mũraika akanange Jerusalemu. No rĩrĩa mũraika ekaga ũguo-rĩ, Jehova akĩona ũndũ ũcio na akĩigua kĩeha nĩ ũndũ wa kĩnyariirĩko kĩu, nake akĩĩra mũraika ũcio wanangaga andũ atĩrĩ, “Tigĩra hau! Eheria guoko gwaku.” Hĩndĩ ĩyo mũraika ũcio wa Jehova aarũgamĩte kĩhuhĩro-inĩ kĩa ngano kĩa Arauna ũrĩa Mũjebusi.
Ọlọ́run sì rán angẹli kan sí Jerusalẹmu láti pa wọ́n run. Ṣùgbọ́n bí angẹli ti ń pa wọ́n run, Olúwa sì wò. Ó sì káàánú nítorí ibi náà, ó sì wí fún angẹli tí ó pa àwọn ènìyàn náà run pé, “Ó ti tó! Dá ọwọ́ rẹ dúró.” Angẹli Olúwa náà sì dúró níbi ilẹ̀ ìpakà Arauna ará Jebusi.
16 Nake Daudi akĩrora igũrũ akĩona mũraika wa Jehova arũngiĩ gatagatĩ ka igũrũ na thĩ acomorete rũhiũ rwa njora, arũnyiitĩte na guoko gwake gũtambũrũkĩirio Jerusalemu. Nake Daudi na athuuri, mehumbĩte nguo cia makũnia, makĩgũa magĩturumithia mothiũ mao thĩ.
Dafidi sì wòkè ó sì rí angẹli Olúwa dúró láàrín ọ̀run àti ayé pẹ̀lú idà fífàyọ ní ọwọ́ rẹ̀ tí ó sì nà án sórí Jerusalẹmu. Nígbà náà Dafidi àti àwọn àgbàgbà, sì wọ aṣọ ọ̀fọ̀, wọ́n sì da ojú wọn bolẹ̀.
17 Daudi akĩũria Ngai atĩrĩ, “Githĩ ti niĩ ndaathanire atĩ arũi a mbaara matarwo? Niĩ nĩ niĩ njĩhĩtie o na ngeeka ũũru. Andũ aya matariĩ o ta ngʼondu. Nĩ atĩa mekĩte? Wee Jehova Ngai wakwa, reke guoko gwaku kũnjũkĩrĩre niĩ na nyũmba yakwa, no rĩrĩ, ndũkareke mũthiro ũyũ ũikare na andũ aku.”
Dafidi sì wí fún Ọlọ́run pé, “Èmi ha kọ́ ni mo pàṣẹ àti ka àwọn jagunjagun ènìyàn? Èmi ni ẹni náà tí ó dẹ́ṣẹ̀ tí ó sì ṣe ohun búburú pàápàá, ṣùgbọ́n bí ó ṣe ti àgùntàn wọ̀nyí, kí ni wọ́n ṣe? Èmí bẹ̀ ọ́ Olúwa Ọlọ́run mi, jẹ́ kí ọwọ́ rẹ kí ó wà lára mi àti àwọn ìdílé baba mi, ṣùgbọ́n má ṣe jẹ́ kí àjàkálẹ̀-ààrùn yìí kí ó dúró lórí àwọn ènìyàn rẹ.”
18 Nake mũraika wa Jehova agĩatha Gadi eere Daudi aambate athiĩ agaakĩre Jehova kĩgongona o kũu kĩhuhĩro-inĩ kĩa ngano kĩa Arauna ũrĩa Mũjebusi.
Nígbà náà angẹli Olúwa náà pàṣẹ fún Gadi láti sọ fún Dafidi pé, kí Dafidi kí ó gòkè lọ, kí ó sì tẹ́ pẹpẹ kan fún Olúwa lórí ilẹ̀ ìpakà Arauna ará Jebusi.
19 Nĩ ũndũ ũcio Daudi akĩambata agĩathĩkĩra kiugo kĩu Gadi aarĩtie thĩinĩ wa rĩĩtwa rĩa Jehova.
Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi sì gòkè lọ pẹ̀lú ìgbọ́ràn sí ọ̀rọ̀ tí Gadi ti sọ ní orúkọ Olúwa.
20 Hĩndĩ ĩrĩa Arauna aakonyoraga ngano-rĩ, akĩĩhũgũra akĩona mũraika ũcio; nao ariũ ake ana arĩa maarĩ nake makĩĩhitha.
Nígbà tí Arauna sì ń pakà lọ́wọ́, ó sì yípadà ó sì rí angẹli; àwọn ọmọ rẹ̀ mẹ́rẹ̀ẹ̀rin tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ pa ará wọn mọ́.
21 Nake Daudi agĩkuhĩrĩria, na rĩrĩa Arauna aarorire akĩmuona, akiuma kĩhuhĩro-inĩ kĩa ngano, akĩinamĩrĩria mũtwe wake mbere ya Daudi, na agĩturumithia ũthiũ thĩ.
Bí Dafidi sì ti dé ọ̀dọ̀ Arauna, Arauna sì wò, ó sì rí Dafidi, ó sì ti ibi ilẹ̀ ìpakà rẹ̀ jáde, ó sì wólẹ̀, ó dojúbolẹ̀ níwájú Dafidi.
22 Daudi akĩmwĩra atĩrĩ, “Njĩtĩkĩria njakĩre Jehova kĩgongona haha kĩhuhĩro-inĩ gĩkĩ gĩaku kĩa ngano, nĩguo mũthiro ũyũ ũkorete andũ ũthire. Nyenderia o ũrĩa thogora wakĩo ũigana.”
Dafidi sì wí fún Arauna pé, “Jẹ́ kí èmi kí ó ni ibi ìpakà rẹ kí èmi kí ó sì lè tẹ́ pẹpẹ kan níbẹ̀ fún Olúwa, ìwọ ó sì fi fún mi ni iye owó rẹ̀ pípé, kí a lè dá àjàkálẹ̀-ààrùn dúró lọ́dọ̀ àwọn ènìyàn.”
23 Arauna akĩĩra Daudi atĩrĩ, “Kĩoe! Reke mũthamaki mwathi wakwa eeke ũndũ ũrĩa ũngĩmũkenia. Na rĩrĩ, nĩngũkũhe ndegwa ici irutwo igongona rĩa njino, ihũũri ici cia ngano ituĩke ngũ, ngano nayo ĩtuĩke ya igongona rĩa mũtu. Icio ciothe nĩngũkũhe.”
Arauna sì wí fún Dafidi pé, “Mú un fún ara rẹ, sì jẹ́ kí olúwa mi ọba kí ó ṣe ohun tí ó dára lójú rẹ̀. Wò ó, èmí yóò fún ọ ní àwọn màlúù fún ẹbọ sísun, àti ohun èlò ìpakà fún igi, àti ọkà fún ọrẹ oúnjẹ. Èmi yóò fun ọ ní gbogbo èyí.”
24 Nowe Mũthamaki Daudi agĩcookeria Arauna atĩrĩ, “Aca, no nginya ndĩhe thogora wakĩo ũrĩa ũigana. Ndingĩrutĩra Jehova kĩndũ gĩaku, kana ndute igongona rĩa njino na kĩndũ kĩrĩa itarutĩire thogora.”
Ṣùgbọ́n ọba Dafidi dá Arauna lóhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́, ṣùgbọ́n èmi yóò rà á ní iye owó rẹ̀ ní pípé, nítorí èmi kì yóò èyí tí ó jẹ́ tìrẹ fún Olúwa, tàbí láti rú ẹbọ sísun tí kò ná mi ní ohun kan.”
25 Nĩ ũndũ ũcio Daudi akĩrĩha Arauna cekeri magana matandatũ cia thahabu nĩ ũndũ wa handũ hau.
Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi san ẹgbẹ̀ta ṣékélì wúrà fún Arauna nípa ìwọ̀n fún ibẹ̀ náà.
26 Daudi agĩakĩra Jehova kĩgongona handũ hau, na akĩruta maruta ma njino na maruta ma ũiguano. Agĩkaĩra Jehova, nake Jehova akĩmwĩtĩka na njĩra ya mwaki uumĩte igũrũ, ũgĩakana kĩgongona-inĩ kĩu kĩa maruta ma njino.
Dafidi sì tẹ́ pẹpẹ fún Olúwa níbẹ̀ ó sì rú ẹbọ sísun àti ẹbọ ọpẹ́. Ó sì ké pe Olúwa, Olúwa sì fi iná dá a lóhùn láti òkè ọ̀run wá lórí pẹpẹ fún ẹbọ ọrẹ sísun.
27 Ningĩ Jehova akĩarĩria mũraika ũcio nake agĩcookia rũhiũ rwake njora.
Nígbà náà Olúwa sọ̀rọ̀ sí angẹli, ó sì gbé idà padà bọ̀ sínú àkọ̀ rẹ̀.
28 Hĩndĩ ĩyo, rĩrĩa Daudi onire atĩ Ngai nĩamũiguĩte arĩ kũu kĩhuhĩro-inĩ kĩa ngano kĩa Arauna ũcio Mũjebusi-rĩ, akĩrutĩra magongona hau.
Ní àkókò náà nígbà tí Dafidi sì rí wí pé Olúwa ti dá a lóhùn lórí ilẹ̀ ìpakà ti Arauna ará Jebusi, ó sì rú ẹbọ sísun níbẹ̀.
29 Hema ya Jehova ĩrĩa nyamũre ĩrĩa Musa aathondekeire werũ-inĩ, na kĩgongona kĩa maruta ma njino, hĩndĩ ĩyo ciarĩ harĩa hatũũgĩru o kũu Gibeoni.
Àgọ́ Olúwa tí Mose ti ṣe ní aginjù, àti pẹpẹ ẹbọ sísun wà lórí ibi gíga ní Gibeoni ní àkókò náà.
30 No rĩrĩ, Daudi ndangĩathiire mbere yakĩo gũtuĩria ũhoro harĩ Ngai tondũ nĩetigagĩra rũhiũ rwa njora rwa mũraika ũcio wa Jehova.
Ṣùgbọ́n Dafidi kò lè lọ síwájú rẹ̀ láti béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run, nítorí tí ó bẹ̀rù nípa idà ọwọ́ angẹli Olúwa.

< 1 Maũndũ 21 >