< 1 Maũndũ 14 >

1 Na rĩrĩ, Hiramu mũthamaki wa Turo, nĩatũmĩire Daudi andũ, marĩ na mĩgogo ya mĩtarakwa, na aaki a mahiga na a mbaũ, nĩguo mamwakĩre nyũmba ya ũthamaki.
Nísinsin yìí Hiramu àti ọba Tire rán oníṣẹ́ sí Dafidi, àti pẹ̀lú igi kedari pẹ̀lú àwọn ọ̀mọ̀lé àti gbẹ́nàgbẹ́nà láti kọ́ ààfin fún un.
2 Nake Daudi nĩamenyire atĩ Jehova nĩamũhaandĩte atuĩke mũthamaki wa Isiraeli, na atĩ ũthamaki wake nĩwatũũgĩrĩtio mũno nĩ ũndũ wa andũ ake a Isiraeli.
Dafidi sì mọ Israẹli àti pé Olúwa ti fi òun ṣe ọba lórí Israẹli àti pé ìjọba rẹ̀ ga jùlọ nítorí ti àwọn ènìyàn rẹ̀.
3 Daudi nĩahikirie atumia angĩ arĩ kũu Jerusalemu, nake agĩtuĩka ithe wa aanake na airĩtu angĩ.
Ní Jerusalẹmu Dafidi mú ọ̀pọ̀ ìyàwó ó sì di baba àwọn ọmọ ọkùnrin púpọ̀ àti ọmọbìnrin.
4 Maya nĩmo marĩĩtwa ma ciana ciake iria ciaciarĩirwo kũu: Shamua, na Shobabu, na Nathani, na Solomoni,
Èyí ni orúkọ àwọn ọmọ náà tí wọ́n bí fún un níbẹ̀: Ṣammua, Ṣobabu, Natani, Solomoni,
5 na Ibiharu, na Elishua, na Elipeleti,
Ibhari, Eliṣua, Elifeleti,
6 na Noga, na Nefegu, na Jafia,
Noga, Nefegi, Jafia,
7 na Elishama, na Beeliada, na Elifeleti.
Eliṣama, Beeliada, àti Elifeleti.
8 Na rĩrĩa Afilisti maaiguire atĩ Daudi nĩaitĩrĩirio maguta agatuĩka mũthamaki wa Isiraeli guothe-rĩ, makĩambata, magĩthiĩ na mbũtũ ciao ciothe makamũcarie, nake Daudi aigua ũhoro ũcio akiumagara, agĩthiĩ akahũũrane nao.
Nígbà tí àwọn ará Filistini gbọ́ pé a ti fi àmì òróró yàn Dafidi ní ọba lórí gbogbo Israẹli, wọ́n sì lọ sókè pẹ̀lú ipá láti wá a rí, ṣùgbọ́n Dafidi gbọ́ nípa rẹ̀ ó sì jáde lọ láti pàdé wọn.
9 Na rĩrĩ, Afilisti nĩmookĩte magatharĩkĩra Gĩtuamba kĩa Refaimu;
Nísinsin yìí àwọn ará Filistini ti wá láti gbógun ti àfonífojì Refaimu;
10 nĩ ũndũ ũcio Daudi agĩtuĩria ũhoro kũrĩ Ngai, akĩmũũria atĩrĩ, “Thiĩ ngatharĩkĩre Afilisti? Nĩũkũmaneana moko-inĩ makwa?” Nake Jehova akĩmũcookeria atĩrĩ, “Thiĩ, nĩngũmaneana moko-inĩ maku.”
Dafidi sì béèrè lọ́dọ̀ Ọlọ́run wí pé, “Kí èmi kí ó gòkè tọ àwọn ará Filistini lọ bí? Ìwọ ó ha fi wọ́n lé mi lọ́wọ́?” Olúwa sì wí fún un pé, “Gòkè lọ èmi ó sì fi wọ́n lé ọ lọ́wọ́.”
11 Nĩ ũndũ ũcio Daudi na andũ ake makĩambata, magĩthiĩ nginya Baali-Perazimu, na akĩmatooreria kuo. Nake akiuga atĩrĩ, “O ta ũrĩa maaĩ moinaga, noguo Ngai aharaganĩtie thũ ciakwa na guoko gwakwa.” Nĩ ũndũ ũcio handũ hau hagĩĩtwo Baali-Perazimu.
Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi àti àwọn ènìyàn rẹ̀ gòkè lọ sí Baali-Perasimu, níbẹ̀ ó sì kọlù wọ́n. Ó sí wí pé, “Gẹ́gẹ́ bí omi tí ya jáde, Ọlọ́run ti ya Dafidi lórí àwọn ọ̀tá mi pẹ̀lú ọwọ́ mi.” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ń pè ibẹ̀ ní Baali-Perasimu.
12 Afilisti magĩtiganĩria ngai ciao kũu, nake Daudi agĩathana ngai icio icinwo na mwaki.
Àwọn ará Filistini sì ti fi àwọn òrìṣà wọn sílẹ̀ níbẹ̀. Dafidi sì pa á láṣẹ láti jó wọn nínú iná.
13 Afilisti nĩmatharĩkĩire Gĩtuamba kĩu rĩngĩ;
Lẹ́ẹ̀kan sí i àwọn ará Filistini gbógun wọ́n sì fọ́nká àfonífojì,
14 nĩ ũndũ ũcio Daudi agĩtuĩria ũhoro harĩ Ngai rĩngĩ, nake Ngai akĩmũcookeria atĩrĩ, “Tiga kwambata, no mathiũrũrũkĩrie, na ũmatharĩkĩre ũmarutĩtie na mbere ya mĩtĩ ya mĩkũngũgũ.
Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi sì tún béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run, Ọlọ́run sì dalóhùn pé, “Má ṣe gòkè tààrà, ṣùgbọ́n ẹ yí wọn ká, kí ẹ sì mú wọn níwájú igi muliberi.
15 Rĩrĩa ũrĩigua mũkubio uumĩte igũrũ rĩa mĩtĩ ĩyo ya mĩkũngũgũ-rĩ, thiĩ ũkarũe, tondũ ũguo nĩkuonania atĩ Ngai arĩ mbere yaku akĩhũũra ita rĩa Afilisti.”
Tí ó bá sì ṣe, tí ẹ̀yin bá ti gbọ́ ìró ẹsẹ̀ ní orí òkè igi muliberi, ẹ jáde fún ogun, nítorí èyí yóò fihàn pé Ọlọ́run ti jáde níwájú rẹ láti kọlu àwọn ọmọ-ogun Filistini.”
16 Nĩ ũndũ ũcio Daudi agĩĩka o ta ũrĩa Ngai aamwathĩte, nao makĩhũũra mbũtũ cia Afilisti, o kuuma Gibeoni nginya Gezeri.
Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi ṣe ohun tí Ọlọ́run ti pàṣẹ fún wọn, wọ́n sì kọlu àwọn ọmọ-ogun Filistini láti gbogbo ọ̀nà Gibeoni lọ sí Geseri.
17 Nĩ ũndũ ũcio ngumo ya Daudi ĩkĩhunja o bũrũri o bũrũri, nake Jehova agĩtũma ndũrĩrĩ ciothe imwĩtigĩre.
Bẹ́ẹ̀ ni òkìkí Dafidi tàn ká gbogbo ilẹ̀ káàkiri, Olúwa sì mú kí gbogbo orílẹ̀-èdè bẹ̀rù rẹ̀.

< 1 Maũndũ 14 >