< 1 Chroniques 8 >

1 Or Benjamin engendra Balé son premier-né, Asbel le second, Ahara le troisième,
Benjamini jẹ́ baba: Bela àkọ́bí rẹ̀, Aṣbeli ọmọkùnrin ni ẹ̀ẹ̀kejì, Ahara ẹ̀ẹ̀kẹ́ta,
2 Nohaa le quatrième, et Rapha le cinquième.
Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
3 Et les fils de Balé furent Addar, Géra et Ahiud,
Àwọn ọmọ Bela ni, Adari, Gera, Abihudi,
4 Abisué aussi, Naaman, et Ahoé;
Abiṣua, Naamani, Ahoa,
5 Mais encore Géra, Séphuphan et Huram.
Gera, Ṣefufani àti Huramu.
6 Ceux-là sont fils d’Ahod, et princes des familles habitant à Gabaa, lesquels furent transférés à Manahath:
Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
7 C’est-à-dire Naaman, et Achia, et Géra; lui-même, Ahod, les transféra, et il engendra Oza et Ahiud.
Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
8 Mais Saharaïm engendra dans la contrée de Moab, après qu’il eut renvoyé Husim et Bara, ses femmes.
A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
9 Il engendra donc de Hodès, sa femme, Joab, Sébia, Mosa et Molchom:
Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
10 Jéhus aussi, et Séchia, et Marma; ceux-là sont ses fils et princes dans leurs familles.
Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
11 Or Méhusim engendra Abitob et Elphaal.
Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
12 Mais les fils d’Elphaal sont Héber, Misaam, et Samad: celui-ci bâtit Ono, et Lod et ses filles,
Àwọn ọmọ Elipali: Eberi, Miṣamu, Ṣemedu (ẹni tí ó kọ́ Ono àti Lodi pẹ̀lú àwọn ìletò àyíká rẹ̀.)
13 Baria et Sama lurent princes des familles habitant à Aïalon: ce sont eux qui chassèrent les habitants de Geth.
Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
14 De plus, Ahio, Sésac, Jérimoth,
Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
15 Zabadia, Arod, Héder,
Sebadiah, Aradi, Ederi
16 Michaël, Jespha et Joha, sont les fils de Baria,
Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
17 Et Zabadia, Mosollam, Hézéci, Aéber,
Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
18 Jésamari, Jezlia et Johab, les fils d’Elphaal;
Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
19 Jacim, Zéchri, Zabdi,
Jakimu, Sikri, Sabdi,
20 Elioénaï, Séléthaï, Eliel,
Elienai, Siletai, Elieli,
21 Adaïa. Baraïa et Samarath, les fils de Séméi;
Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
22 Jespham, Héber, Eliel,
Iṣipani Eberi, Elieli,
23 Abdon, Zéchri, Hanan,
Abdoni, Sikri, Hanani,
24 Hanania, Aelam, Anathothia,
Hananiah, Elamu, Anitotijah,
25 Jephdaïa et Phanuel, les fils de Sésac;
Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
26 Samsari, Sohoria, Otholia,
Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
27 Jersia, Elia et Zéchri, les fils de Jéroham.
Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
28 Ce sont là les patriarches et les princes des familles qui ont habité à Jérusalem.
Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
29 Mais à Gabaod habitèrent Abigabaaon, dont le nom de la femme était Maacha;
Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni. Ìyàwó o rẹ̀ a má jẹ́ Maaka,
30 Son fils, premier-né, Abdon, et les autres, Sur, Cis, Baal et Nadab,
àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
31 Et aussi Gédor, Ahio, Zacher et Macelloth;
Gedori Ahio, Sekeri
32 Et Macelloth engendra Samaa; et ils habitèrent vis-à-vis de leurs frères, à Jérusalem, avec leurs frères.
pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
33 Or Ner engendra Cis, et Cis engendra Saül. Mais Saül engendra Jonathan, Melchisua, Abinadab et Esbaal.
Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
34 Et le fils de Jonathan fut Méribbaal, et Méribbaal engendra Micha.
Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali tí ó jẹ́ baba Mika.
35 Les fils de Micha furent Phithon, Mélech, Tharaa et Ahaz,
Àwọn ọmọ Mika: Pitoni, Meleki, Tarea, àti Ahasi.
36 Et Ahaz engendra Joada, et Joada engendra Alamath, Azmoth et Zamri: or Zamri engendra Mosa;
Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
37 Et Mosa engendra Banaa, dont le fils fut Rapha, de qui est né Elasa, qui engendra Asel.
Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
38 Or Asel eut six fils de ces noms: Ezricam, Bocru, Ismaël, Saria, Obdia et Hanan: tous ceux-là furent fils d’Asel.
Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn: Asrikamu, Bokeru, Iṣmaeli, Ṣeariah, Obadiah àti Hanani. Gbogbo wọ̀nyí ni ọmọ Aseli.
39 Mais les fils d’Esec, son frère: Ulam, le premier-né, Jéhus, le second, et Eliphalet, le troisième.
Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki: Ulamu àkọ́bí rẹ̀, Jeuṣi ọmọkùnrin ẹ̀ẹ̀kejì àti Elifeleti ẹ̀ẹ̀kẹ́ta.
40 Et les fils d’Ulam furent des hommes très vigoureux et tendant l’arc avec une grande force; ayant beaucoup de fils et de petits-fils, jusqu’à cent cinquante. Tous ceux-là sont les fils de Benjamin.
Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀. Gbogbo wọ̀nyí ni àwọn ìdílé ìran ọmọ Benjamini.

< 1 Chroniques 8 >