< 1 Chroniques 3 >

1 Or voici les fils qu’eut David, qui lui naquirent à Hébron: l’aîné, Amnon, fils d’Achinoam de Jezrahel; le second, Daniel, fils d’Abigaïl du Carmel;
Àwọn wọ̀nyí sì ni ọmọ Dafidi tí a bí fún un ní Hebroni. Àkọ́bí sì ni Amnoni ọmọ Ahinoamu ti Jesreeli; èkejì sì ni Daniẹli ọmọ Abigaili ará Karmeli;
2 Le troisième, Absalom, fils de Maacha, fille de Tholmaï, roi de Gessur; le quatrième, Adonias, fils d’Aggith;
ẹ̀kẹta sì ni Absalomu ọmọ Maaka ọmọbìnrin Talmai ọba Geṣuri bí fún un; ẹ̀kẹrin sì ni Adonijah ọmọ Haggiti;
3 Le cinquième, Saphatias, qu’il eut d’Abital; le sixième, Jéthraham, fils d’Egla, sa femme.
ẹ̀karùnún ni Ṣefatia láti ọ̀dọ̀ Abitali; àti ẹ̀kẹfà, Itreamu, láti ọ̀dọ̀ Egla aya rẹ̀.
4 Il lui naquit donc six fils à Hébron, où il régna sept ans et un mois. Mais il régna trente-trois ans à Jérusalem.
Àwọn mẹ́fà wọ̀nyí ni a bí fún Dafidi ni Hebroni, níbi tí ó ti jẹ ọba fún ọdún méje àti oṣù mẹ́fà. Dafidi sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n.
5 Or, à Jérusalem, voici les fils qui lui naquirent: Simmaa, Sobab, Nathan, Salomon, quatre qu’il eut de Bethsabée, fille d’Ammiel;
Wọ̀nyí ni ọmọ wẹ́wẹ́ tí a bí fún un ní Jerusalẹmu: Ṣimea, Ṣobabu, Natani àti Solomoni. Àwọn mẹ́rin wọ̀nyí sì ni a bí láti ọ̀dọ̀ Bati-Ṣua ọmọbìnrin Ammieli.
6 De plus Jébaar et Elisama,
Ibhari sì wà pẹ̀lú, Eliṣama, Elifeleti,
7 Eliphaleth, Nogé, Népheg et Japhia,
Noga, Nefegi, Jafia,
8 Comme aussi Elisama, Eliada et Eliphéleth: en tout, neuf.
Eliṣama, Eliada àti Elifeleti mẹ́sàn-án ni wọ́n.
9 Ce sont là tous les fils de David, outre les fils de ses femmes du second rang; et ils eurent une sœur, Thamar.
Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Dafidi yàtọ̀ sí àwọn ọmọ tí àlè bí fún un. Tamari sì ni arábìnrin wọn.
10 Or le fils de Salomon fut Roboam, dont le fils Abia engendra Asa; de celui-ci aussi est né Josaphat,
Ọmọ Solomoni ni Rehoboamu, Abijah ọmọ rẹ̀, Asa ọmọ rẹ̀, Jehoṣafati ọmọ rẹ̀,
11 Père de Joram, qui engendra Ochozias, duquel est né Joas;
Jehoramu ọmọ rẹ̀, Ahasiah ọmọ rẹ̀, Joaṣi ọmọ rẹ̀,
12 Dont le fils Amasias engendra Azarias. Or le fils d’Azarias, Joathan,
Amasiah ọmọ rẹ̀, Asariah ọmọ rẹ̀, Jotamu ọmọ rẹ̀,
13 Procréa Achaz, père d’Ezéchias, dont naquit Manassé.
Ahasi ọmọ rẹ̀, Hesekiah ọmọ rẹ̀, Manase ọmọ rẹ̀,
14 Mais Manassé aussi engendra Amon, père de Josias.
Amoni ọmọ rẹ̀, Josiah ọmọ rẹ̀.
15 Or les fils de Josias furent: le premier-né, Johanan; le second, Joakim; le troisième, Sédécias; le quatrième, Sellum.
Àwọn ọmọ Josiah: àkọ́bí ọmọ rẹ̀ ni Johanani, èkejì ọmọ rẹ̀ ni Jehoiakimu, ẹ̀kẹta ọmọ rẹ̀ ni Sedekiah, ẹ̀kẹrin ọmọ rẹ̀ ni Ṣallumu.
16 De Joakim naquit Jéchonias, puis Sédécias.
Àwọn ìran ọmọ Jehoiakimu: Jekoniah ọmọ rẹ̀, àti Sedekiah.
17 Les fils de Jéchonias furent Asir, Salathiel,
Àwọn ọmọ Jekoniah tí a mú ní ìgbèkùn: Ṣealitieli ọmọ rẹ̀ ọkùnrin,
18 Melchiram, Phadaïa, Sennéser et Jécémia, Sama et Nadabia.
Malkiramu, Pedaiah, Ṣenasari, Jekamiah, Hoṣama àti Nedabiah.
19 De Phadaïa sont nés Zorobabel et Séméi. Zorobabel engendra Mosollam, et Hananias et Salomith leur sœur;
Àwọn ọmọ Pedaiah: Serubbabeli àti Ṣimei. Àwọn ọmọ Serubbabeli: Meṣullamu àti Hananiah. Ṣelomiti ni arábìnrin wọn.
20 Et encore, Hasabas, Ohol, Barachias, Hasadias et Josabhesed: en tout, cinq.
Àwọn márùn-ún mìíràn sì tún wà: Haṣuba, Oheli, Berekiah, Hasadiah àti Jusabhesedi.
21 Or le fils d’Hananias fut Phaltias, père de Jéséias, dont le fils fut Raphaïa, et le fils de celui-ci, Arnan, duquel naquit Obdia, dont le fils fut Séchénias;
Àwọn ọmọ Hananiah: Pelatiah àti Jeṣaiah, àti àwọn ọmọ Refaiah, ti Arnani, ti Obadiah àti ti Ṣekaniah.
22 Le fils de Séchénias, Séméia, dont les fils furent Hattus, Jégaal, Baria, Naaria et Saphat; au nombre de six.
Àwọn ọmọ Ṣekaniah: Ṣemaiah àti àwọn ọmọ rẹ̀: Hattusi, Igali, Bariah, Neariah àti Ṣafati, mẹ́fà ni gbogbo wọn.
23 Les fils de Naarias, Elioénaï, Ezéchias et Ezricam; trois.
Àwọn ọmọ Neariah: Elioenai; Hesekiah, àti Asrikamu, mẹ́ta ni gbogbo wọn.
24 Les fils d’Elioénaï: Oduïa, Eliasub, Phéléia, Accub, Johanan, Dalaïa et Anani; sept.
Àwọn ọmọ Elioenai: Hodafiah, Eliaṣibu, Pelaiah, Akkubu, Johanani, Delaiah àti Anani, méje sì ni gbogbo wọn.

< 1 Chroniques 3 >