< 1 Chroniques 8 >

1 Et Benjamin engendra Béla, son premier-né, Asbel, le second, et Aherach, le troisième,
Benjamini jẹ́ baba: Bela àkọ́bí rẹ̀, Aṣbeli ọmọkùnrin ni ẹ̀ẹ̀kejì, Ahara ẹ̀ẹ̀kẹ́ta,
2 Noha, le quatrième, et Rapha le cinquième.
Noha ẹ̀ẹ̀kẹrin àti Rafa ẹ̀karùnún.
3 Et Béla eut des fils: Addar et Géra, et Abihud
Àwọn ọmọ Bela ni, Adari, Gera, Abihudi,
4 et Abisua et Naaman et Ahoah
Abiṣua, Naamani, Ahoa,
5 et Géra et Sepuphan et Huram.
Gera, Ṣefufani àti Huramu.
6 Et suivent les fils d'Ehud, lesquels furent les patriarches des habitants de Géba, et ils les emmenèrent captifs à Manachath,
Wọ̀nyí ni àwọn ìran ọmọ Ehudu, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé tí ó ń gbé ní Geba tí a sì lé kúrò lọ sí Manahati:
7 savoir Naaman et Ahia et Géra, c'est celui-ci qui les emmena captifs, et il engendra Uzza et Ahihud.
Naamani Ahijah àti Gera, tí ó lé wọn kúrò ní ìlú, àti tí ó sì jẹ́ baba Ussa àti Ahihudu.
8 Et Sacharaïm engendra dans la campagne de Moab, après les avoir répudiées, avec Husim et Baara, ses femmes, des fils.
A bí àwọn ọmọkùnrin fún Ṣaharaimu ní Moabu lẹ́yìn tí ó ti kọ àwọn ìyàwó rẹ̀ sílẹ̀, Huṣimu àti Baara.
9 Et il eut de Hodès, sa femme, Jobab et Tsibia et Meisa et Malcam
Nípasẹ̀ ìyàwó rẹ̀ Hodeṣi ó ní Jobabu Sibia, Meṣa, Malkamu,
10 et Jehuts et Sochia et Mirma. Tels sont ses fils, patriarches.
Jeusi, Sakia àti Mirma. Wọ̀nyí ni àwọn ọmọkùnrin rẹ̀, olórí àwọn ìdílé.
11 Et de Husim il eut Abitub et Elpaal.
Nípasẹ̀ Huṣimu ó ní Abitubu àti Elipali.
12 Et les fils d'Elpaal: Eber et Miseam et Samer, lequel bâtit Ono et Lod et ses annexes.
Àwọn ọmọ Elipali: Eberi, Miṣamu, Ṣemedu (ẹni tí ó kọ́ Ono àti Lodi pẹ̀lú àwọn ìletò àyíká rẹ̀.)
13 Et Bria et Sema sont les patriarches des habitants d'Ajalon; ils mirent en fuite les habitants de Gath.
Pẹ̀lú Beriah àti Ṣema, tí wọ́n jẹ́ olórí àwọn ìdílé ti àwọn tí ó ń gbé ní Aijaloni àti àwọn tí ó lé àwọn olùgbé Gati kúrò.
14 Et Ahio, Sasac et Jerémoth
Ahio, Ṣasaki, Jeremoti,
15 et Zebadia et Arad et Ader
Sebadiah, Aradi, Ederi
16 et Michaël et Jispa et Joah sont les fils de Bria.
Mikaeli, Iṣifa àti Joha jẹ́ àwọn ọmọ Beriah.
17 Et Zebadia et Mesullam et Hiski et Haber
Sebadiah, Meṣullamu, Hiski, Heberi
18 et Jismeraï et Jizlia et Jobab sont les fils d'Elpaal.
Iṣimerai, Isiliahi àti Jobabu jẹ́ àwọn ọmọ Elipali.
19 Et Jakim et Zichri et Zabdi
Jakimu, Sikri, Sabdi,
20 et Elioeinaï et Tsilthaï et Eliel
Elienai, Siletai, Elieli,
21 et Adaïa et Beraïa et Simrath sont les fils de Siméï.
Adaiah, Beraiah àti Ṣimrati jẹ́ àwọn ọmọ, Ṣimei.
22 Et Jispan et Héber et Eliel
Iṣipani Eberi, Elieli,
23 et Abdon et Zichri et Hanan
Abdoni, Sikri, Hanani,
24 et Hanania et Eilam et Anthothia
Hananiah, Elamu, Anitotijah,
25 et Jiphdia et Pnuel sont les fils de Sasac.
Ifediah àti Penueli jẹ́ àwọn ọmọ Ṣasaki.
26 Et Samseraï et Secharia et Athalia
Ṣamṣerai, Ṣeharaiah, Ataliah
27 et Jaerseia et Elia et Zichri sont les fils de Jeroham.
Jareṣiah, Elijah àti Sikri jẹ́ àwọn ọmọ Jerohamu.
28 Ce sont des patriarches d'après leurs familles, des chefs: ils habitaient à Jérusalem.
Gbogbo àwọn wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn ìdílé, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìran wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
29 Et à Gabaon habitait le père de Gabaon, et le nom de sa femme était Maacha.
Jeieli, baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni. Ìyàwó o rẹ̀ a má jẹ́ Maaka,
30 Et son fils premier-né était Abdon, et [les autres] Tsur et Kis et Baal et Nadab
àkọ́bí rẹ̀ a sì máa jẹ́ Abdoni wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu,
31 et Gedor et Ahio et Zacher.
Gedori Ahio, Sekeri
32 Et Micloth engendra Simea et eux aussi habitaient en face de leurs frères à Jérusalem avec leurs frères.
pẹ̀lú Mikiloti, tí ó jẹ́ baba Ṣimea. Wọ́n ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
33 Et Ner engendra Kis, et Kis engendra Saül, et Saül engendra Jonathan et Maleki-Sua et Abinadab et Esbaal.
Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba Saulu àti Saulu baba Jonatani, Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
34 Et le fils de Jonathan fut Meribbaal, et Meribbaal engendra Micha.
Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali tí ó jẹ́ baba Mika.
35 Et les fils de Micha sont: Pithon et Mélech et Thaërèa et Achaz.
Àwọn ọmọ Mika: Pitoni, Meleki, Tarea, àti Ahasi.
36 Et Achaz engendra Joadda, et Joadda engendra Alemeth et Azmaveth et Zimri, et Zimri engendra Motsa.
Ahasi jẹ́ baba a Jeheada, Jeheada jẹ́ baba a Alemeti, Asmafeti àti Simri, Simri sì jẹ́ baba Mosa.
37 Et Motsa engendra Binea, dont le fils fut Rapha qui ont pour fils Eleasa, dont le fils fut Atsel.
Mosa jẹ́ baba Binea; Rafa sì jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
38 Et Atsel eut six fils dont les noms suivent: Azricam, Bochru et Ismaël et Séaria et Obadia et Hanan: tout autant de fils de Atsel.
Aseli ní ọmọ mẹ́fà pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn: Asrikamu, Bokeru, Iṣmaeli, Ṣeariah, Obadiah àti Hanani. Gbogbo wọ̀nyí ni ọmọ Aseli.
39 Et les fils de Esec son frère: Ulam, son premier-né, Jeüs, le second, et Elipheleth, le troisième.
Àwọn ọmọ arákùnrin rẹ̀ Eseki: Ulamu àkọ́bí rẹ̀, Jeuṣi ọmọkùnrin ẹ̀ẹ̀kejì àti Elifeleti ẹ̀ẹ̀kẹ́ta.
40 Et les fils d'Ulam furent de braves guerriers, bandant l'arc, et ils eurent beaucoup de fils et de petits-fils, cent cinquante. Tous ceux-là sont d'entre les fils de Benjamin.
Àwọn ọmọ Ulamu jẹ́ ògboyà jagunjagun tí ó lè gbá orin mú. Wọ́n ní ọ̀pọ̀ ọmọkùnrin àti ọmọ ọmọkùnrin áàdọ́jọ ní gbogbo rẹ̀. Gbogbo wọ̀nyí ni àwọn ìdílé ìran ọmọ Benjamini.

< 1 Chroniques 8 >