< Hoosean 6 >
1 Tulkaa, palatkaamme Herran tykö, sillä hän on raadellut meitä, ja parantaa meidät, hän on lyönyt meitä, ja sitoo meidät.
“Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a padà sọ́dọ̀ Olúwa ó ti fà wá ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ ṣùgbọ́n yóò mú wa láradá Ó ti pa wá lára ṣùgbọ́n yóò dí ojú ọgbẹ́ wa.
2 Hän tekee meidät eläviksi kahden päivän kuluttua, kolmantena päivänä hän meidät herättää, ja me saamme elää hänen edessänsä.
Lẹ́yìn ọjọ́ méjì, yóò sọ wá jí ní ọjọ́ kẹta yóò mú wa padà bọ̀ sípò kí a ba à le wá gbé níwájú rẹ̀.
3 Niin tuntekaamme, pyrkikäämme tuntemaan Herra: hänen nousunsa on varma kuin aamurusko, hän tulee meille kuin sade, kuin kevätsade, joka kostuttaa maan.
Ẹ jẹ́ kí a mọ Olúwa; ẹ jẹ́ kí a tẹ̀síwájú láti mọ̀ ọ́n. Gẹ́gẹ́ bí oòrùn ṣe ń yọ, yóò jáde; yóò tọ̀ wá wá bí òjò, bí òjò àkọ́rọ̀ ti ń bomirin ilẹ̀.”
4 Mitä on minun tehtävä sinulle, Efraim, mitä on minun tehtävä sinulle, Juuda, kun teidän rakkautenne on kuin aamun pilvi, kuin varhain haihtuva kaste?
“Kí ni èmi ó ṣe pẹ̀lú rẹ, Efraimu? Kí ni èmi ó ṣe pẹ̀lú rẹ, Juda? Ìfẹ́ rẹ dàbí ìkùùkuu òwúrọ̀ bí ìrì ìdájí tí ó kọjá lọ kíákíá.
5 Sentähden minä olen antanut heille iskuja profeettain kautta, olen kuolettanut heitä suuni sanoilla. Ja sinun tuomiosi nousevat kuin aamun valo.
Nítorí náà ni mo ṣe gé e yín sí wẹ́wẹ́ láti ọwọ́ àwọn wòlíì, Mo pa yín pẹ̀lú ọ̀rọ̀ ẹnu mi, ìdájọ́ mi tàn bí i mọ̀nàmọ́ná lórí yín.
6 Sillä laupeutta minä haluan enkä uhria, ja Jumalan tuntemista enemmän kuin polttouhreja;
Nítorí àánú ni mo fẹ́, kì í ṣe ẹbọ; àti ìmọ̀ Ọlọ́run ju ọrẹ ẹbọ sísun lọ.
7 mutta he ovat ihmisten tavalla rikkoneet liiton: siinä he ovat olleet minulle uskottomat.
Bí i Adamu, wọ́n da májẹ̀mú wọ́n jẹ́ aláìṣòótọ́ sí mi níbẹ̀.
8 Gilead on pahantekijäin kaupunki, täynnä veren jälkiä.
Gileadi jẹ́ ìlú àwọn ènìyàn búburú tí ń ṣiṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀, a sí ti fi ẹ̀ṣẹ̀ bà á jẹ́.
9 Ja väijyväisten rosvojen kaltainen on pappien joukko: he murhaavat Sikemin tiellä; ilkitöitä he tekevät.
Bí adigunjalè ṣe ń ba ní bùba de àwọn ènìyàn bẹ́ẹ̀ ni àwọn àlùfáà, ń parapọ̀; tí wọ́n sì ń pànìyàn lójú ọ̀nà tó lọ sí Ṣekemu, tí wọ́n sì ń dá ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ti ni lójú.
10 Israelin heimon keskuudessa minä olen nähnyt kauhistuttavia tekoja: siellä on Efraimin haureus, Israel on itsensä saastuttanut.
Mo ti rí ohun tó ba ni lẹ́rù ní ilé Israẹli. Níbẹ̀ Efraimu, fi ara rẹ̀ fún àgbèrè Israẹli sì di aláìmọ́.
11 Myös sinun varallesi, Juuda, on asetettu elonleikkuu, silloin kun minä käännän kansani kohtalon.
“Àti fún ìwọ, Juda, a ti yan ọjọ́ ìkórè rẹ. “Nígbà tí mo bá fẹ́ dá ohun ìní àwọn ènìyàn mi padà,