< Jesajan 21 >
1 Tämä on korven kuorma meren tykönä: niinkuin tuulispää tulee etelästä, joka kääntää ylösalaisin, niin se tulee korvesta, kauhiasta maasta.
Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan aginjù lẹ́bàá Òkun. Gẹ́gẹ́ bí ìjì líle ti í jà kọjá ní gúúsù, akógunjàlú kan wá láti aginjù, láti ilẹ̀ ìpayà.
2 Sillä minulle on osoitettu kova näky: pettäjä tulee toista vastaan, hävittäjä toista vastaan. Mene ylös Elam, piiritä heitä Madai: minä lopetan kaikki hänen huokauksensa.
Ìran tí a ń fojú ṣọ́nà fún ni a ti fihàn mí ọlọ̀tẹ̀ ti tu àṣírí, fọ́lé fọ́lé ti kẹ́rù. Elamu kojú ìjà! Media ti tẹ̀gùn! Èmi yóò mú gbogbo ìpayínkeke dópin, ni ó búra.
3 Sentähden ovat minun kupeeni täynnä kipua, ja ahdistus on minun käsittänyt, niinkuin lapsen synnyttäjän ahdistus; minä kyyristän minuni, koska minä sen kuulen, ja peljästyn, koska minä sen näen.
Pẹ̀lú èyí, ìrora mu mi lára gírígírí, ìrora gbá mi mú, gẹ́gẹ́ bí i ti obìnrin tí ń rọbí, mo ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n nítorí ohun tí mo gbọ́, ọkàn mi pòruurù nípa ohun tí mo rí.
4 Minun sydämeni vapisee, kauhistus on minun peljättänyt; sentähden ei ole minulla ollut suloisella yöllä yhtään lepoa.
Ọkàn mí dàrú, ẹ̀rù mú jìnnìjìnnì bá mi, ìmọ́lẹ̀ tí mo ti ń fẹ́ ẹ́ rí ti wá di ìpayà fún mi.
5 Valmista pöytä, anna valvojain valvoa, syö, juo: nouskaat te pääruhtinaat ja voidelkaat kilvet.
Wọ́n tẹ́ tábìlì, wọ́n tẹ́ ẹní àtẹ́ẹ̀ká, wọ́n jẹ, wọ́n mu! Dìde nílẹ̀, ẹ̀yin ọmọ-aládé, ẹ fi òróró kún asà yín!
6 Sillä Herra sanoo näin minulle: mene ja toimita vartio, joka katselis ja ilmoittais.
Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún mi: “Lọ, kí o bojúwòde kí o sì wá sọ ohun tí ó rí.
7 Mutta hän näki ratsastajat ajavan ja menevän aaseilla ja kameleilla, ja piti siitä visun vaarin.
Nígbà tí ó bá rí àwọn kẹ̀kẹ́ ogun àti àkójọpọ̀ àwọn ẹṣin, àwọn tó ń gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tàbí àwọn tí ó gun ìbákasẹ, jẹ́ kí ó múra sílẹ̀, àní ìmúra gidigidi.”
8 Ja hän huusi niinkuin jalopeura: Herra, minä olen vartiolla yli päivää, ja olen minun vartiollani kaikki yöt:
Òun sì kígbe pé, kìnnìún kan, “Láti ọjọ́ dé ọjọ́, olúwa mi, mo dúró lórí ilé ìṣọ́ ní ọ̀sán, a sì fi mí ìṣọ́ mi ní gbogbo òru.
9 Ja katso, siellä tulee yksi vaunuissa ja kaksi ratsahin, joka vastaa ja sanoo: kaatunut, kaatunut on Babylon, ja kaikki hänen jumalainsa kuvat lyötiin maahan.
Wò ó, ọkùnrin kan ni ó ń bọ̀ wá yìí nínú kẹ̀kẹ́ ogun àti àkójọpọ̀ àwọn ẹṣin. Ó sì mú ìdáhùn padà wá: ‘Babeli ti ṣubú, ó ti ṣubú! Gbogbo àwọn ère òrìṣà rẹ̀ ló fọ́nká sórí ilẹ̀!’”
10 O minun tappamiseni ja minun riiheni permanto! mitä minä olen Herralta Zebaotilta, Israelin Jumalalta, kuullut, sen minä teille ilmoitan.
Ẹ̀yin ènìyàn mi, tí a gún mọ́lẹ̀ ní ilẹ̀ ìpakà, mo sọ ohun tí mo ti gbọ́ láti ọ̀dọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun, láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Israẹli.
11 Tämä on Duman kuorma: Seiristä huudetaan minua: vartia, mitä yö kuluu? vartia, mitä yö kuluu?
Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Dumahi. Ẹnìkan ké sí mi láti Seiri wá, “Alóre, kí ló kù nínú òru náà?”
12 Vartia sanoi: kuin aamu tulee, niin vielä yö on; jos te vielä kysytte, niin teidän pitää vielä sitte palajaman ja taas kysymän.
Alóre náà dáhùn wí pé, “Òwúrọ̀ súnmọ́ tòsí, àti òru náà pẹ̀lú. Bí ìwọ yóò bá béèrè, béèrè; kí o sì tún padà wá.”
13 Tämä on Arabian kuorma: teidän pitää yötymän Arabian metsässä, Dedanimin tiellä.
Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Arabia. Ẹ̀yin ẹgbẹ́ èrò ti Dedani, tí ó pàgọ́ sínú igbó Arabia,
14 Kantakaat vettä janoovaa vastaan, te jotka asutte Temanin maassa: taritkaat pakenevaisille leipää.
gbé omi wá fún àwọn tí òǹgbẹ ń gbẹ; ẹ̀yin tí ó ń gbé Tema, gbé oúnjẹ wá fún àwọn ìsáǹsá.
15 Sillä he pakenevat miekkaa, paljasta miekkaa, jännitettyä jousta ja isoa sotaa.
Wọ́n sá kúrò lọ́wọ́ idà, kúrò lọ́wọ́ idà tí a fàyọ, kúrò lọ́wọ́ ọrun tí a fàyọ àti kúrò nínú ìgbóná ogun.
16 Sillä näin sanoo Herra minulle: vielä nyt vuosi, niinkuin palkollisen vuodet ovat, niin pitää kaiken Kedarin kunnian hukkuman.
Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún mi: “Láàrín ọdún kan, gẹ́gẹ́ bí ìwọ̀fà tí ó wà lábẹ́ ọgbà, í ti í kà á, gbogbo ògo ìlú Kedari yóò wá sí òpin.
17 Ja jääneet ampujat, väkevät Kedarin lapsista, pitää vähemmäksi joutuman; sillä Herra Israelin Jumala on sen sanonut.
Àwọn tafàtafà tí ó sálà, àwọn jagunjagun ìlú Kedari kò ní tó nǹkan.” Olúwa, Ọlọ́run Israẹli ni ó ti sọ̀rọ̀.