< Aamoksen 8 >

1 Herra, Herra osoitti minulle näyssä, ja katso, siellä oli kori suvituloa.
Èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè fihàn mi: agbọ̀n èso pípọ́n.
2 Ja hän sanoi: mitäs näet, Amos? minä vastasin: korin suvituloa. Niin Herra sanoi minulle: minun kansani Israelin loppu on tullut, en minä tahdo enään mennä häntä ohitse.
Ó béèrè pé, “Amosi kí ni ìwọ rí.” Mo sì dáhùn pé, “Agbọ̀n èso pípọ́n.” Nígbà náà ni Olúwa wí fún mi pé, “Àsìkò náà pọ́n tó fún àwọn ènìyàn mi Israẹli; Èmi kì yóò dá wọn sí mọ́.”
3 Ja sinä päivänä pitää veisut templissä itkuksi kääntymän, sanoo Herra, Herra; monta kuollutta ruumista pitää joka paikassa makaaman, jotka viedään salassa pois.
Olúwa Olódùmarè wí pé, “Ní ọjọ́ náà, àwọn orin tẹmpili yóò yí padà sí ohùn réré ẹkún. Ọ̀pọ̀, àní ọ̀pọ̀ ara òkú ni yóò wà ni ibi gbogbo! Àní ni ìdákẹ́ jẹ́ẹ́!”
4 Kuulkaat tätä te, jotka köyhää sorratte, ja vaivaisia maakunnassa hävitätte,
Ẹ gbọ́ èyí, ẹ̀yin tí ń tẹ aláìní lórí ba, tí ẹ sì ń sọ tálákà di ilẹ̀.
5 Ja sanotte: koska uusi kuu loppuu, että me saisimme jyviä myydä; ja sabbati, että me ohria kauppaisimme, ja mitan vähentäisimme, ja hinnan korottaisimme, ja vaa'at vääriksi tekisimme;
Tí ẹ ń wí pé, “Nígbà wo ni oṣù tuntun yóò parí kí àwa bá à lè ta ọkà kí ọjọ́ ìsinmi kí ó lè dópin kí àwa bá à le ta jéró?” Kí a sì dín ìwọ̀n wa kù kí a gbéraga lórí iye tí a ó tà á kí a sì fi òsùwọ̀n èké yàn wọ́n jẹ,
6 Että me saisimme köyhät rahallamme haltuumme ja hätäytyneet kenkäparilla, ja myisimme akanat jyväin edestä?
kí àwa lè fi fàdákà ra àwọn tálákà, kí a sì fi bàtà ẹsẹ̀ méjèèjì ra aláìní, kí a sì ta jéró tí a kó mọ́ ilẹ̀.
7 Herra on vannonut Jakobin korkeutta vastaan: mitämaks, jos minä ikänä kaikki ne heidän työnsä unohdan.
Olúwa ti fi ìgbéraga Jakọbu búra pé, “Èmi kì yóò gbàgbé ọ̀kan nínú ohun tí wọ́n ṣe.
8 Eikö maan sentähden pitäisi vapiseman, ja kaikki sen asuvaiset murehtiman? Ja pitää nouseman kaiken sen päälle niinkuin virta, vietämän pois ja upotettaman niinkuin Egyptin virralla.
“Ǹjẹ́ ilẹ̀ náà kì yóò ha wárìrì fún èyí? Àwọn tí ń gbé inú rẹ̀ kì yóò ha ṣọ̀fọ̀? Gbogbo ilẹ̀ yóò ru sókè bí omi Naili, yóò sì ru ú sókè pátápátá bí ìkún omi a ó sì tì í jáde, a ó sì tẹ̀ ẹ́ rì gẹ́gẹ́ bí odò Ejibiti.
9 Sillä ajalla, sanoo Herra, Herra, tahdon minä laskea auringon alas puolipäivästä, ja pimittää maan valkialla päivällä.
“Yóò sì ṣe ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa Olódùmarè wí, “Èmi yóò mú oòrùn wọ̀ ní ọ̀sán, Èmi yóò mú kí ayé ṣókùnkùn ní ọ̀sán gangan.
10 Minä tahdon teidän juhlapäivänne kääntää murheeksi, ja kaikki teidän veisunne valitukseksi, ja tahdon antaa säkin jokaisen kupeisiin tulla, ja kaikki päät paljaaksi tehdä; ja tahdon heille murheen saattaa, niinkuin joku ainoaa poikaa murehtii; ja heidän pitää surkian lopun saaman.
Èmí yóò yí àsè ẹ̀sìn yín padà sí ọ̀fọ̀, gbogbo orin yín ni èmi yóò sọ di ẹkún. Èmi yóò mú kí gbogbo yín wọ aṣọ ọ̀fọ̀, kí a sì fá orí yín. Èmi yóò mú kí ìgbà náà rí bí ìṣọ̀fọ̀ fún ọmọkùnrin kan ṣoṣo tí a bí àti òpin rẹ̀ bí ọjọ́ kíkorò.
11 Katso, ne päivät tulevat, sanoo Herra, Herra, että minä lähetän nälän maan päälle; ei nälkää leivän perään, eli janoa veden perään, vaan Herran sanan kuulemisen jälkeen,
“Ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa Olódùmarè wí, “nígbà tí èmi yóò rán ìyàn sí ilẹ̀ náà, kì í ṣe ìyàn oúnjẹ tàbí òǹgbẹ fún omi. Ṣùgbọ́n ìyàn gbígbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa.
12 Niin että heidän pitää juokseman yhdestä merestä niin toiseen, pohjasta niin itään; heidän pitää juoksenteleman etsimään Herran sanaa, ja ei kuitenkaan pidä löytämän.
Àwọn ènìyàn yóò rìn kiri láti Òkun dé Òkun wọn yóò sì máa rìn ká láti gúúsù sí àríwá, wọn yóò máa wá ọ̀rọ̀ Olúwa ṣùgbọ́n wọn kì yóò rí i.
13 Sinä päivänä pitää kauniit neitseet ja nuorukaiset nääntymän janosta.
“Ní ọjọ́ náà “àwọn arẹwà wúńdíá àti àwọn alágbára ọ̀dọ́mọkùnrin yóò dákú fún òǹgbẹ omi.
14 Ja jotka nyt Samarian rikoksen kautta vannovat ja sanovat: niin totta kuin sinun jumalas Danissa elää, niin totta kuin sinun jumalas Bersebassa elää: niiden pitää niin lankeeman, ettei he voi jälleen nousta ylös.
Àwọn tí ó fi ẹ̀ṣẹ̀ Samaria búra, tí wọ́n sì wí pé, ‘Bí ó ti dájú pé ọlọ́run rẹ ń bẹ láààyè, ìwọ Dani,’ bí ó ti dájú pè ọlọ́run rẹ ń bẹ láààyè, ìwọ Beerṣeba, wọ́n yóò ṣubú, wọn kì yóò si tún dìde mọ.”

< Aamoksen 8 >