< Psalms 25 >
Ti Dafidi. Olúwa, ìwọ ni mo gbé ọkàn mi sókè sí.
2 Lord, to thee Y haue reisid my soule; my God, Y truste in thee, be Y not aschamed.
Ọlọ́run, èmi gbẹ́kẹ̀lé ọ; má ṣe jẹ́ kí ojú ó tì mí má ṣe jẹ́ kí àwọn ọ̀tá mi ó yọ̀ mí.
3 Nethir myn enemyes scorne me; for alle men that suffren thee schulen not be schent.
Ẹni tí ó dúró tì ọ́ ojú kì yóò tì í, àwọn tí ń ṣẹ̀ láìnídìí ni kí ojú kí ó tì.
4 Alle men doynge wickyd thingis superfluli; be schent. Lord, schewe thou thi weies to me; and teche thou me thi pathis.
Fi ọ̀nà rẹ hàn mí, Olúwa, kọ mi ní ipa tìrẹ;
5 Dresse thou me in thi treuthe, and teche thou me, for thou art God my sauyour; and Y suffride thee al dai.
ṣe amọ̀nà mi nínú òtítọ́ ọ̀ rẹ, kí o sì kọ́ mi, nítorí ìwọ ni Ọlọ́run ìgbàlà mi; ìwọ ni mo dúró tì ní gbogbo ọjọ́.
6 Lord, haue thou mynde of thi merciful doyngis; and of thi mercies that ben fro the world.
Rántí, Olúwa àánú àti ìfẹ́ ẹ̀ rẹ̀ ńlá, torí pé wọ́n ti wà ní ìgbà àtijọ́.
7 Haue thou not mynde on the trespassis of my yongthe; and on myn vnkunnyngis. Thou, Lord, haue mynde on me bi thi merci; for thi goodnesse.
Má ṣe rántí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ ìgbà èwe mi tàbí ìrékọjá mi; gẹ́gẹ́ bí i ìfẹ́ ẹ rẹ̀ rántí mi nítorí tí ìwọ dára, Ìwọ! Olúwa.
8 The Lord is swete and riytful; for this he schal yyue a lawe to men trespassynge in the weie.
Rere àti ẹni ìdúró ṣinṣin ní Olúwa: nítorí náà, ó kọ́ àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ ni ọ̀nà náà.
9 He schal dresse deboner men in doom; he schal teche mylde men hise weies.
Ó ṣe amọ̀nà àwọn onírẹ̀lẹ̀ ni ohun tí ó dára, ó sì kọ́ àwọn onírẹ̀lẹ̀ ní ọ̀nà rẹ̀.
10 Alle the weies of the Lord ben mercy and treuthe; to men sekynge his testament, and hise witnessyngis.
Gbogbo ipa ọ̀nà Olúwa ni ìfẹ́ àti òdodo tí ó dúró ṣinṣin, fún àwọn tí ó pa májẹ̀mú àti ẹ̀rí rẹ̀ mọ́.
11 Lord, for thi name thou schalt do merci to my synne; for it is myche.
Nítorí orúkọ rẹ, Olúwa, dárí ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ mi jì mí, nítorí tí ó tóbi.
12 Who is a man, that dredith the Lord? he ordeyneth to hym a lawe in the weie which he chees.
Àwọn wo ni ó bẹ̀rù Olúwa? Yóò kọ́ wọn ní ọ̀nà èyí tí wọn yóò yàn.
13 His soule schal dwelle in goodis; and his seed schal enerite the lond.
Wọn yóò lo ọjọ́ wọn nínú àlàáfíà, àwọn ọmọ wọn yóò sì gba ilẹ̀ náà.
14 The Lord is a sadnesse to men dredynge hym; and his testament is, that it be schewid to hem.
Olúwa fi ọkàn tán, àwọn tí o bẹ̀rù u rẹ̀; ó sọ májẹ̀mú rẹ̀ di mí mọ̀ fún wọn.
15 Myn iyen ben euere to the Lord; for he schal breide awey my feet fro the snare.
Ojú mi gbé sókè sọ́dọ̀ Olúwa, nítorí pé yóò yọ ẹsẹ̀ mi kúrò nínú àwọ̀n náà.
16 Biholde thou on me, and haue thou mercy on me; for Y am
Yípadà sí mi, kí o sì ṣe oore fún mi; nítorí pé mo nìkan wà, mo sì di olùpọ́njú.
17 oon aloone and pore The tribulaciouns of myn herte ben multiplied; delyuere thou me of my nedis.
Tì mí lẹ́yìn kúrò nínú ìpọ́njú àyà mi; kí o sì fà mí yọ kúrò nínú ìpọ́njú mi.
18 Se thou my mekenesse and my trauel; and foryyue thou alle my trespassis.
Kíyèsi ìjìyà àti wàhálà mi, kí o sì dárí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ mi jì.
19 Bihold thou myn enemyes, for thei ben multiplied; and thei haten me bi wickid hatrede.
Kíyèsi ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ọ̀tá mi, tí wọn kórìíra mi pẹ̀lú ìwà ìkà wọn.
20 Kepe thou my soule, and delyuere thou me; be Y not aschamed, for Y hopide in thee.
Pa ọkàn mi mọ́, kí o sì gbà mí sílẹ̀; má ṣe jẹ́ kí a fi mí sínú ìtìjú, nítorí pé ìwọ ni ibi ìsádi mi.
21 Innocent men and riytful cleuyden to me; for Y suffride thee.
Jẹ́ kí òtítọ́ inú àti ìdúró ṣinṣin kí ó pa mí mọ́; nítorí pé mo dúró tì ọ́.
22 God, delyuere thou Israel; fro alle hise tribulaciouns.
Ra Israẹli padà, Ìwọ Ọlọ́run, nínú gbogbo ìṣòro rẹ̀!