< Isaiah 62 >
1 Because I am very concerned about [the people of] Jerusalem [DOU], I will do something to help them. I will not stop praying for them until they are rescued/freed [from their oppressors], until that becomes as apparent to everyone as the dawn [every morning], until people can see it as clearly as [SIM] they see a torch shining brightly [at night].
Nítorí Sioni èmi kì yóò dákẹ́, nítorí i Jerusalẹmu èmi kì yóò sinmi ẹnu, títí tí òdodo rẹ̀ yóò fi tàn bí òwúrọ̀, àti ìgbàlà rẹ̀ bí i fìtílà tí ń jó geere.
2 [Some day] the [people of many] nations will know that Yahweh has rescued you, [his people]. Their kings will see that your city is [very] great/glorious. And Yahweh [MTY] will give your [city] a new name.
Àwọn orílẹ̀-èdè yóò rí òdodo rẹ, àti gbogbo ọba ògo rẹ a ó sì máa pè ọ́ ní orúkọ mìíràn èyí tí ẹnu Olúwa yóò fi fún un.
3 [It will be as though] Yahweh will hold you up in his hands in order that everyone can see you. Under his authority [MTY], you will be [like] a glorious headband/turban worn by a king.
Ìwọ yóò sì jẹ́ adé dídán ní ọwọ́ Olúwa, adé ọba ní ọwọ́ Ọlọ́run rẹ.
4 Your [city] will never again be called “the deserted/abandoned city” and your country will never again be called “the desolate land”; it will be called “the land that Yahweh delights in”, and [it will also be called] “married to Yahweh”. It will be called that because Yahweh will be delighted with you, [and it will be as though] you are his bride [MET].
Wọn kì yóò pè ọ́ ní ìkọ̀sílẹ̀ mọ́ tàbí kí wọ́n pe ilẹ̀ rẹ ní ahoro. Ṣùgbọ́n a ó máa pè ọ́ ní Hẹfsiba, àti ilẹ̀ rẹ ní Beula; nítorí Olúwa yóò yọ́nú sí ọ àti ilẹ̀ rẹ ni a ó gbé níyàwó.
5 You people will live in all the country of Judah like [SIM] a young man lives with his bride. And our God will be happy that you [belong to] him like [SIM] a bridegroom is happy that his bride [belongs to him].
Gẹ́gẹ́ bí ọ̀dọ́mọkùnrin tí í gbé ọ̀dọ́mọbìnrin níyàwó, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọkùnrin rẹ yóò gbé ọ níyàwó Gẹ́gẹ́ bí ọkọ ìyàwó ṣe é yọ̀ lórí ìyàwó rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni Ọlọ́run rẹ yóò yọ̀ lórí rẹ.
6 [You people of] Jerusalem, I have placed watchmen on your walls; they will [LIT] earnestly pray to Yahweh day and night. You watchmen, you must not stop [praying] [and] reminding Yahweh [about what he has promised to do]!
Èmi ti fi olùṣọ́ ránṣẹ́ sórí odi rẹ ìwọ Jerusalẹmu; wọn kì yóò lè dákẹ́ tọ̀sán tòru. Ẹ̀yin tí ń ké pe Olúwa, ẹ má ṣe fúnra yín ní ìsinmi,
7 And tell Yahweh that he should not rest until he causes Jerusalem to be [a city that is] famous throughout the world.
àti kí ẹ má ṣe fún òun pẹ̀lú ní ìsinmi títí tí yóò fi fi ìdí Jerusalẹmu múlẹ̀ tí yóò sì fi ṣe ìyìn orí ilẹ̀ ayé.
8 Yahweh has raised his right hand to solemnly promise [to the people of Jerusalem], “I will use my power [MTY] and never again allow your enemies to defeat you; [soldiers from other nations will never come again] to take away your grain and the wine that you worked hard [to produce].
Olúwa ti búra pẹ̀lú ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀ àti nípa agbára apá rẹ: “Èmi kì yóò jẹ́ kí ìyẹ̀fun rẹ di oúnjẹ fún ọ̀tá rẹ bẹ́ẹ̀ ni àwọn àjèjì kì yóò mu wáìnì tuntun rẹ mọ́ èyí tí ìwọ ti ṣe làálàá fún;
9 You yourselves grew the grain, and you will be the ones who will praise [me], Yahweh, while you eat [the bread made from] that grain. Inside the courtyards of my temple you yourselves will drink the wine made from the grapes [that you harvested].”
ṣùgbọ́n àwọn tí ó bá kóórè rẹ̀ ni yóò jẹ ẹ́, tí wọn ó sì yin Olúwa, àti àwọn tí wọ́n bá kó àjàrà jọ ni wọn ó mú un, nínú àgbàlá ilé mímọ́ mi.”
10 Go out through the [city] gates! Prepare the highway on which people [will return from other countries]! Cause the road to become smooth; clear off [all] the stones; set up signal flags to help the people-groups to see [where the road to Jerusalem is].
Ẹ kọjá, ẹ kọjá ní ẹnu ibodè náà! Ẹ tún ọ̀nà ṣe fún àwọn ènìyàn. Ẹ mọ ọ́n sókè, ṣe ojú ọ̀nà òpópó! Ẹ ṣa òkúta kúrò. Ẹ gbé àsíá sókè fún àwọn orílẹ̀-èdè.
11 This is the message that Yahweh has sent to [the people of] every nation: “Tell the people of Israel, ‘The one who will rescue/save you is coming! Look! He will be bringing to you (your reward/what you deserve [for the good things that you have done]); those whom he is setting free will be going ahead of him.’”
Olúwa ti ṣe ìkéde títí dé òpin ilẹ̀ ayé: “Ẹ sọ fún ọmọbìnrin Sioni pé, ‘Kíyèsi i, Olùgbàlà rẹ ń bọ̀! Kíyèsi i, èrè ń bẹ pẹ̀lú rẹ̀, àti ẹ̀san rẹ̀ pẹ̀lú n tẹ̀lé e lẹ́yìn.’”
12 They will be called “Yahweh’s own people, the ones whom he rescued”. And Jerusalem will be known as the city that [Yahweh] loves, the city that is no [longer] abandoned.
A ó sì pè wọ́n ní Ènìyàn Mímọ́, ẹni ìràpadà Olúwa; a ó sì máa pè ọ́ ní ìwákiri, ìlú tí a kì yóò kọ̀sílẹ̀.