< Psalms 136 >

1 Give thanks to YHWH, For [He is] good, for His kindness [is] for all time.
Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí tí ó ṣeun;
2 Give thanks to the God of gods, For His kindness [is] for all time.
Ẹ fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run àwọn ọlọ́run:
3 Give thanks to the Lord of lords, For His kindness [is] for all time.
Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa àwọn olúwa,
4 To Him doing great wonders by Himself alone, For His kindness [is] for all time.
Fún Òun nìkan tí ń ṣiṣẹ́ ìyanu ńlá;
5 To Him making the heavens by understanding, For His kindness [is] for all time.
Fún ẹni tí ó fi ọgbọ́n dá ọ̀run;
6 To Him spreading the earth over the waters, For His kindness [is] for all time.
Fún ẹni tí ó tẹ́ ilẹ̀ lórí omi;
7 To Him making great lights, For His kindness [is] for all time.
Fún ẹni tí ó dá àwọn ìmọ́lẹ̀ ńlá;
8 The sun to rule by day, For His kindness [is] for all time.
Òòrùn láti jẹ ọba ọ̀sán;
9 The moon and stars to rule by night, For His kindness [is] for all time.
Òṣùpá àti ìràwọ̀ láti jẹ ọba òru;
10 To Him striking Egypt in their firstborn, For His kindness [is] for all time.
Fún ẹni tí ó kọlu Ejibiti lára àwọn àkọ́bí wọn;
11 And bringing forth Israel from their midst, For His kindness [is] for all time.
Ó sì mú Israẹli jáde kúrò láàrín wọn;
12 By a strong hand and an outstretched-arm, For His kindness [is] for all time.
Pẹ̀lú ọwọ́ agbára àti apá nínà;
13 To Him cutting the Sea of Suph into parts, For His kindness [is] for all time,
Fún ẹni tí ó pín Òkun pupa ní ìyà;
14 And caused Israel to pass through its midst, For His kindness [is] for all time,
Ó sì mú Israẹli kọjá láàrín rẹ̀
15 And shook out Pharaoh and his force in the Sea of Suph, For His kindness [is] for all time.
Ṣùgbọ́n ó bi Farao àti ogun rẹ̀ ṣubú nínú Òkun pupa;
16 To Him leading His people in a wilderness, For His kindness [is] for all time.
Fún ẹni tí ó sin àwọn ènìyàn rẹ̀ la aginjù já
17 To Him striking great kings, For His kindness [is] for all time.
Fún ẹni tí ó kọlu àwọn ọba ńlá;
18 Indeed, He slays majestic kings, For His kindness [is] for all time.
Ó sì pa àwọn ọba olókìkí
19 Even Sihon king of the Amorite, For His kindness [is] for all time.
Sihoni, ọba àwọn ará Amori
20 And Og king of Bashan, For His kindness [is] for all time.
Àti Ogu, ọba Baṣani;
21 And He gave their land for inheritance, For His kindness [is] for all time.
Ó sì fi ilẹ̀ wọn fún ni ní ìní,
22 An inheritance to Israel His servant, For His kindness [is] for all time.
Ìní fún Israẹli, ìránṣẹ́ rẹ̀,
23 Who has remembered us in our lowliness, For His kindness [is] for all time.
Ẹni tí ó rántí wa ní ìwà ìrẹ̀lẹ̀ wa;
24 And He delivers us from our adversaries, For His kindness [is] for all time.
Ó sì dá wa ní ìdè lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa;
25 Giving food to all flesh, For His kindness [is] for all time.
Ẹni tí ó fi oúnjẹ fún àwọn ẹ̀dá gbogbo
26 Give thanks to the God of the heavens, For His kindness [is] for all time!
Ẹ fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run ọ̀run;

< Psalms 136 >