< Psalms 136 >
1 Give thanks to the LORD, for he is good, for his loving kindness endures forever.
Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí tí ó ṣeun;
2 Give thanks to the God of gods, for his loving kindness endures forever.
Ẹ fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run àwọn ọlọ́run:
3 Give thanks to the Lord of lords, for his loving kindness endures forever;
Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa àwọn olúwa,
4 to him who alone does great wonders, for his loving kindness endures forever;
Fún Òun nìkan tí ń ṣiṣẹ́ ìyanu ńlá;
5 to him who by understanding made the heavens, for his loving kindness endures forever;
Fún ẹni tí ó fi ọgbọ́n dá ọ̀run;
6 to him who spread out the earth above the waters, for his loving kindness endures forever;
Fún ẹni tí ó tẹ́ ilẹ̀ lórí omi;
7 to him who made the great lights, for his loving kindness endures forever;
Fún ẹni tí ó dá àwọn ìmọ́lẹ̀ ńlá;
8 the sun to rule by day, for his loving kindness endures forever;
Òòrùn láti jẹ ọba ọ̀sán;
9 the moon and stars to rule by night, for his loving kindness endures forever;
Òṣùpá àti ìràwọ̀ láti jẹ ọba òru;
10 to him who struck down the Egyptian firstborn, for his loving kindness endures forever;
Fún ẹni tí ó kọlu Ejibiti lára àwọn àkọ́bí wọn;
11 and brought out Israel from among them, for his loving kindness endures forever;
Ó sì mú Israẹli jáde kúrò láàrín wọn;
12 with a strong hand, and with an outstretched arm, for his loving kindness endures forever;
Pẹ̀lú ọwọ́ agbára àti apá nínà;
13 to him who divided the Red Sea apart, for his loving kindness endures forever;
Fún ẹni tí ó pín Òkun pupa ní ìyà;
14 and made Israel to pass through the middle of it, for his loving kindness endures forever;
Ó sì mú Israẹli kọjá láàrín rẹ̀
15 but overthrew Pharaoh and his army in the Red Sea, for his loving kindness endures forever;
Ṣùgbọ́n ó bi Farao àti ogun rẹ̀ ṣubú nínú Òkun pupa;
16 to him who led his people through the wilderness, for his loving kindness endures forever;
Fún ẹni tí ó sin àwọn ènìyàn rẹ̀ la aginjù já
17 to him who struck great kings, for his loving kindness endures forever;
Fún ẹni tí ó kọlu àwọn ọba ńlá;
18 and killed mighty kings, for his loving kindness endures forever;
Ó sì pa àwọn ọba olókìkí
19 Sihon king of the Amorites, for his loving kindness endures forever;
Sihoni, ọba àwọn ará Amori
20 Og king of Bashan, for his loving kindness endures forever;
Àti Ogu, ọba Baṣani;
21 and gave their land as an inheritance, for his loving kindness endures forever;
Ó sì fi ilẹ̀ wọn fún ni ní ìní,
22 even a heritage to Israel his servant, for his loving kindness endures forever;
Ìní fún Israẹli, ìránṣẹ́ rẹ̀,
23 who remembered us in our low estate, for his loving kindness endures forever;
Ẹni tí ó rántí wa ní ìwà ìrẹ̀lẹ̀ wa;
24 and has delivered us from our adversaries, for his loving kindness endures forever;
Ó sì dá wa ní ìdè lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa;
25 who gives food to every creature, for his loving kindness endures forever.
Ẹni tí ó fi oúnjẹ fún àwọn ẹ̀dá gbogbo
26 Oh give thanks to the God of heaven, for his loving kindness endures forever.
Ẹ fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run ọ̀run;