< Kwan 14 >

1 Otienono oganda duto mag gwengʼ notingʼo dwondgi malo mi giywak matek.
Gbogbo ìjọ ènìyàn sì gbóhùn sókè, wọ́n sì sọkún ní òru ọjọ́ náà.
2 Jo-Israel duto nongʼur ne Musa kod Harun, kendo chokruok mar oganda duto nowachonegi niya, “Donge dine ber ka watho Misri? Kata mana e thim ka!
Gbogbo ọmọ Israẹli sì kùn sí Mose àti Aaroni, gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli sì wí fún wọn pé, “Àwa ìbá kúkú ti kú ní ilẹ̀ Ejibiti. Tàbí kí a kúkú kú sínú aginjù yìí.
3 Angʼo momiyo Jehova Nyasaye kelowa e pinyni mondo negwa gi ligangla? Mondewa kod nyithindwa ibiro kaw mana kaka gik moyaki. Donge deber ka wadok Misri?”
Kí ló dé tí Olúwa fi mú wa wá sí ilẹ̀ yìí láti fi idà pa wá? Àwọn ìyàwó wa, àwọn ọmọ wa yóò sì di ìjẹ. Ǹjẹ́ kò wa, ní í dára fún wa bí a bá padà sí Ejibiti?”
4 Kendo negiwacho e kindgi giwegi niya, “Onego wayier jatelo mondo wadog Misri.”
Wọ́n sì sọ fún ara wọn pé, “Ẹ jẹ́ kí á yan olórí kí á sì padà sí Ejibiti.”
5 Eka Musa kod Harun nopodho auma e nyim chokruok mar oganda Israel duto mane ochokore kanyo.
Nígbà náà ni Mose àti Aaroni dojúbolẹ̀ níwájú gbogbo ìjọ ọmọ Israẹli.
6 Joshua wuod Nun kod Kaleb wuod Jefune, ma gin achiel kuom joma ne odhi nono piny Kanaan, noyiecho lepgi
Joṣua ọmọ Nuni àti Kalebu ọmọ Jefunne, tí wọ́n wà lára àwọn to lọ yẹ ilẹ̀ wò sì fa aṣọ wọn ya.
7 mi owacho ne chokruok mar oganda jo-Israel duto niya, “Piny mane wakalo e iye kendo wanono ber miwuoro.
Wọ́n sì sọ fún gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli pé, “Ilẹ̀ tí a là kọjá láti yẹ̀ wò náà jẹ́ ilẹ̀ tí ó dára lọ́pọ̀lọ́pọ̀.
8 Ka dipo ni Jehova Nyasaye mor kodwa, to obiro telonwa nyaka e pinyno, piny mopongʼ gi chak kod mor kich, kendo obiro miyowa pinyno.
Bí inú Olúwa bá dùn sí wa, yóò mú wa dé ilẹ̀ náà, ilẹ̀ tó ń sàn fún wàrà àti fún oyin, yóò fún wa ní ilẹ̀ náà.
9 Gima utim en ni kik ungʼanyne Jehova Nyasaye. Kik uluor jopinyno, nikech wabiro mwonyogi duto. Jarit mag-gi osea, to wan to Jehova Nyasaye nikodwa kendo kik uluorgi.”
Ṣùgbọ́n ẹ má ṣe ṣọ̀tẹ̀ sí Olúwa. Kí ẹ sì má bẹ̀rù àwọn ènìyàn ìlú náà, nítorí pé a ó gbé wọn mì, ààbò wọn ti fi wọ́n sílẹ̀, Olúwa sì wà pẹ̀lú àwa, ẹ má ṣe bẹ̀rù wọn.”
10 To chokruok mar oganda duto nowuoyo e kindgi giwegi mondo gichielgi gi kite. Eka duongʼ mar Jehova Nyasaye nothinyore ne jo-Israel duto e Hemb Romo.
Ṣùgbọ́n gbogbo ìjọ ènìyàn sì ń sọ pé àwọn yóò sọ wọ́n lókùúta pa. Nígbà náà ni ògo Olúwa fi ara hàn ní àgọ́ ìpàdé níwájú àwọn ọmọ Israẹli.
11 Jehova Nyasaye nowacho ne Musa niya, “Nyaka karangʼo ma jogi biro jarae? Nyaka karangʼo ma jogi biro tamore yie kuoma, kata bangʼ timo honni mopogore opogore e kindgi?
Olúwa sọ fún Mose pé, “Fún ìgbà wo ni àwọn ènìyàn yìí yóò ti kẹ́gàn mi tó? Báwo ni yóò ti pẹ́ tó tí wọ́n ó fi kọ̀ jálẹ̀ láti gbà mí gbọ́, pẹ̀lú gbogbo iṣẹ́ àmì tí mo ṣe láàrín wọn?
12 Abiro negogi gi masira mi atiekgi chuth, to un to abiro miyou ubed oganda maduongʼ kendo motegno moloyogi.”
Èmi ó kọlù wọ́n pẹ̀lú àjàkálẹ̀-ààrùn, èmi ó gba ogún wọn lọ́wọ́ wọn, èmi ó sì pa wọ́n run ṣùgbọ́n èmi ó sọ ọ́ di orílẹ̀-èdè ńlá tó sì lágbára jù wọ́n lọ.”
13 Musa noywak ne Jehova Nyasaye niya, “Jo-Misri ongʼeyo wachni malongʼo ni in ema nigolo jo-Israel oa kuomgi gi tekoni iwuon.
Ṣùgbọ́n Mose sọ fún Olúwa pé, “Nígbà náà ni àwọn ará Ejibiti yóò gbọ́! Nítorí pé nípa agbára rẹ ni ìwọ fi mú àwọn ènìyàn wọ̀nyí jáde kúrò láàrín wọn.
14 Kendo gibiro nyiso jopinyni wachni. To bende gisewinjo ni in, yaye Jehova Nyasaye, oseneni kitelonegi godiechiengʼ gi boche mag polo, to gotieno itelonegi gi pilni mar mach.
Wọ́n ó sì sọ fún àwọn olùgbé ilẹ̀ yìí. Àwọn tó ti mọ̀ tẹ́lẹ̀ pé ìwọ Olúwa wà láàrín àwọn ènìyàn wọ̀nyí àti pé wọ́n rí ìwọ, Olúwa, ní ojúkojú, àti pé ìkùùkuu àwọsánmọ̀ rẹ dúró lórí wọn, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ sì ń lọ níwájú wọn pẹ̀lú ìkùùkuu àwọsánmọ̀ ní ọ̀sán àti pẹ̀lú ọ̀wọ́n iná ní òru.
15 Ka inego jogi duto dichiel, to oganda mabiro winjo wach machalo kama kuomi biro wacho niya,
Bí ìwọ bá pa àwọn ènìyàn wọ̀nyí lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo, àwọn orílẹ̀-èdè tó bá gbọ́ ìròyìn yìí nípa rẹ yóò wí pé,
16 ‘Jehova Nyasaye ne ok nyal chopo gi jogi e piny mane osingorenegi kokwongʼore, momiyo ne onegogi e thim.’
‘Nítorí pé Olúwa kò le è mú àwọn ènìyàn wọ̀nyí dé ilẹ̀ tí ó ṣèlérí fún wọn; torí èyí ló ṣe pa wọ́n sínú aginjù yìí.’
17 “Mad koro teko Jehova Nyasaye oyangre malongʼo, mana kaka isewacho:
“Báyìí, mo gbàdúrà, jẹ́ kí agbára Olúwa tóbi gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti sọ pé,
18 ‘Jehova Nyasaye ok kech piyo, to en gihera mogundho kendo oweyo ne ji richogi kendo ongʼwono ne joma ongʼanyo. To kata kamano, joma oketho ok nyal we ma ok okum; okumo nyithindo kuom richo mag wuonegi nyaka tiengʼ mar adek kata nyaka tiengʼ mar angʼwen.’
‘Olúwa lọ́ra láti bínú, ó sì pọ̀ ní ìfẹ́ tó dúró ṣinṣin, tí ń dárí ẹ̀ṣẹ̀ àti ìrékọjá jì. Bẹ́ẹ̀ ni kì í jẹ́ kí ẹlẹ́bi lọ láìjìyà; tó ń fi ìyà ẹ̀ṣẹ̀ baba jẹ ọmọ títí dé ìran kẹta àti ìran kẹrin.’
19 Kaluwore gihera mari maduongʼ, yie iwene jogi richo mag-gi, mana kaka isebedo ka ingʼwononegi chakre gia Misri nyaka sani.”
Dárí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn yìí jì wọ́n, mo bẹ̀ ọ́, gẹ́gẹ́ bí ìfẹ́ ńlá rẹ, bí o ti ṣe ń dárí ẹ̀ṣẹ̀ wọn jì wọ́n láti ìgbà tí o ti kó wọn kúrò ní Ejibiti di ìsin yìí.”
20 Jehova Nyasaye nodwoko niya, “Aseweyonegi richogi mana kaka ne ikwayo.
Olúwa sì dáhùn pé, “Mo ti dáríjì wọ́n gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ rẹ.
21 Kata kamano, akwongʼora gi nyinga awuon kod duongʼ mara mopongʼo piny,
Ṣùgbọ́n nítòótọ́ bí mo ti wà láààyè, gbogbo ayé yóò kún fún ògo Olúwa.
22 ni onge kata mana ngʼato achiel kuomgi mane oneno duongʼ mara kod ranyisi mag honni mane atimo Misri kendo e thim, to ne ok owinja kendo otema nyadipar; ma nochopi e piny mane asingonegi.
Kò sí ọ̀kan nínú àwọn ènìyàn tó rí ògo mi àti àwọn iṣẹ́ àmì tí mo ṣe ní ilẹ̀ Ejibiti àti nínú aginjù ṣùgbọ́n tí wọ́n ṣe àìgbọ́ràn sí mi, tí wọn sì dán mi wò ní ìgbà mẹ́wàá yìí,
23 Bende onge kata mana ngʼato achiel kuomgi mabiro neno piny mane asingone kweregi ka akwongʼora. Ngʼato angʼata ma osenyisa achaya ok none pinyno.
ọ̀kan nínú wọn kò ní rí ilẹ̀ náà tí mo ṣe ìlérí ní ìbúra láti fún baba ńlá wọn. Kò sí ọ̀kan nínú àwọn tó kẹ́gàn mi tí yóò rí ilẹ̀ náà.
24 To nikech jatichna Kaleb nigi chuny mopogore kod mag-gi kendo ma luwa gi chunye duto, abiro tere e piny mane odhiyoeno, kendo nyikwaye nokaw pinyno kaka girkeni margi.
Ṣùgbọ́n nítorí pé Kalebu ìránṣẹ́ mi ní ẹ̀mí ọ̀tọ̀, tí ó sì tún tẹ̀lé mi tọkàntọkàn, èmi ó mu dé ilẹ̀ náà tó lọ yẹ̀ wò, irú àwọn ọmọ rẹ̀ yóò sì jogún rẹ̀.
25 To nikech jo-Amalek kod jo-Kanaan odak e kuonde mag holo, dwoguru kiny kendo udhi e thim mantiere e yo mochiko Nam Makwar.”
Níwọ́n ìgbà tí àwọn ará Amaleki àti àwọn ará Kenaani ń gbé ní àfonífojì, ẹ yípadà lọ́la kí ẹ sì dojúkọ aginjù lọ́nà Òkun Pupa.”
26 Jehova Nyasaye nowacho ne Musa kod Harun niya,
Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni pé,
27 “Nyaka karangʼo ma oganda ma timbegi richogi biro ngʼur koda? Asewinjo ngʼur mar jo-Israel ma jo-mibadhigi.
“Báwo ni yóò ti pẹ́ tó tí àwọn ìjọ ènìyàn búburú yìí yóò fi máa kùn sí mi? Mo ti gbọ́ kíkùn tí àwọn ọmọ Israẹli ń kùn sí mi.
28 Omiyo nyisgiuru ni Jehova Nyasaye owacho ni, ‘Akwongʼora gi nyinga awuon, ni abiro timonu mana gigo mane awinjo kuwacho:
Sọ fún wọn, bí mo ti wà láààyè nítòótọ́ ni Olúwa wí, gẹ́gẹ́ bí ohun tí ẹ wí létí mi ni èmi ó ṣe fún un yín.
29 Ringreu nolwar mana e thimni; ngʼato angʼata kuomu ma hike piero ariyo ka dhi nyime mane okwan e ndalo kweno kendo mosengʼur koda.
Nínú aginjù yìí ni ẹ ó kú sí, gbogbo ẹ̀yin tí ẹ kùn láti ọmọ ogún ọdún ó lé àní gbogbo ẹ̀yin tí a kà.
30 Onge ngʼato angʼata kuomu manodonji e piny mane asingone katingʼo bada malo mondo obed dalau, makmana Kaleb wuod Jefune kod Joshua wuod Nun.
Ọ̀kan nínú yín kò ní í dé ilẹ̀ tí mo búra nípa ìgbọ́wọ́sókè láti fi ṣe ibùgbé yín, bí kò ṣe Kalebu ọmọ Jefunne àti Joṣua ọmọ Nuni.
31 To kuom nyithindu mane uwacho ni ibiro kaw kaka gik moyaki, gin to abiro kelogi mondo giyud mor mar piny mane udagi.
Ṣùgbọ́n ní ti àwọn ọmọ yín tí ẹ wí pé wọn ó di ìjẹ, àwọn ni n ó mú dé bẹ̀ láti gbádùn ilẹ̀ tí ẹ kọ̀sílẹ̀.
32 To un, ringreu nodongʼ e thim.
Ṣùgbọ́n ẹ̀yin, òkú yín yóò ṣubú ní aginjù yìí.
33 Nyithindu nobed jokwath e pinyni kuom higni piero angʼwen, ka giyudo thagruok nikech bedou maonge gi ratiro, nyaka ane ni ringre ngʼama ogik odongʼ e thim.
Àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ yín yóò sì máa rin kiri nínú aginjù fun ogójì ọdún wọn ó máa jìyà nítorí àìnígbàgbọ́ yín, títí tí ọkàn gbogbo yín yóò fi ṣòfò tán ní aginjù.
34 Ne ubet ka unono pinyno kuom ndalo piero angʼwen, omiyo unuchul richou kuom higni piero angʼwen, ka higa achiel ikwano kar ndalo achiel, mi unufweny malongʼo gima omiyo akwedou.’
Fún ogójì ọdún èyí jẹ́ ọdún kan fún ọjọ́ kọ̀ọ̀kan nínú ogójì ọjọ́ tí ẹ fi yẹ ilẹ̀ náà wò ẹ̀yin ó sì jìyà fún ẹ̀ṣẹ̀ yín, ẹ ó sì mọ bí ó ti rí láti lòdì sí mi.
35 An, Jehova Nyasaye, asewacho, kendo abiro timo gigi adieri ne oganda ma timbegi richogi, moseriwore mar kweda. Giko mar ngimagi notimre e thim; kendo kae ema gibiro thoe.”
Èmi, Olúwa, lo sọ bẹ́ẹ̀; Èmi ó sì ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí sí ìjọ ènìyàn búburú yìí tí wọ́n kó ra wọn jọ lòdì sí mi. Nínú aginjù yìí ni òpin yóò dé bá wọn, ibẹ̀ ni wọn yóò kú sí.”
36 Omiyo joma Musa ne oseoro mondo odhi onon pinyno, mi odwogo kendo omiyo oganda duto ma timbegi richogi ongʼur kode kaluwore gi wach marach mane gikelo kuom pinyno;
Àwọn ọkùnrin tí Mose rán láti yẹ ilẹ̀ wò, tí wọ́n sì mú gbogbo ìjọ kùn sí i nípa ìròyìn búburú tí wọ́n mú wá nípa ilẹ̀ náà;
37 jogi mane okelo wach marachni kuom pinyno noneg-gi gi masira e nyim Jehova Nyasaye.
Olúwa sì kọlu àwọn ọkùnrin tó mú ìròyìn búburú wá nípa ilẹ̀ náà, àjàkálẹ̀-ààrùn sì pa wọ́n níwájú Olúwa.
38 Kuom joma nodhi nono pinyno, Joshua wuod Nun kod Kaleb wuod Jefune kende ema notony.
Nínú gbogbo àwọn tó lọ yẹ ilẹ̀ náà wò, Joṣua ọmọ Nuni àti Kalebu ọmọ Jefunne ló yè é.
39 Ka Musa nowacho ne jo-Israel duto wachni kendo ne giywak gi lit ahinya.
Nígbà tí Mose sọ gbogbo ọ̀rọ̀ yìí fún àwọn ọmọ Israẹli, wọ́n sì sọkún gidigidi.
40 Kiny gokinyi mangʼich ne giwuok mi gidhi e piny manie got. Negiwacho niya, “Wasetimo richo. Wabiro dhi nyaka kama Jehova Nyasaye nosingo.”
Wọ́n dìde ní àárọ̀ ọjọ́ kejì wọ́n sì gòkè lọ sí ìlú orí òkè, wọ́n wí pé, “Àwa ti ṣẹ̀, àwa yóò lọ sí ibi tí Olúwa ṣèlérí fún wa.”
41 To Musa nowachonegi niya, “Angʼo momiyo utamoru winjo chik Jehova Nyasaye? Mano ok bi timore!
Mose sì dá wọn lóhùn pé, “Kí ló dé tí ẹ fi ṣẹ̀ sí òfin Olúwa? Èyí kò le yọrí sí rere!
42 Kik udhi kuno, nikech Jehova Nyasaye oseweyou. Wasiku biro lou,
Ẹ má ṣe gòkè lọ nítorí pé Olúwa kò sí láàrín yín. Ki á má ba à lù yín bolẹ̀ níwájú àwọn ọ̀tá yín.
43 nimar jo-Amalek kod jo-Kanaan noked kodu kuno. Nikech useweyo Jehova Nyasaye, ok enodhi kodu kendo nonegu gi ligangla.”
Nítorí pé àwọn ará Amaleki àti àwọn ará Kenaani ń bẹ níwájú yín, ẹ̀yin yóò sì ti ipa idà ṣubú. Nítorí pé, ẹ ti yà kúrò ní ọ̀nà Olúwa, Olúwa kò sì ní í wà pẹ̀lú yín.”
44 To kata kamano, ne ok gidewo wachno, mi gichako dhi malo e piny got, to Musa kata Sandug Muma mar Jehova Nyasaye ne ok owuok e kambi.
Síbẹ̀síbẹ̀, pẹ̀lú àìfarabalẹ̀ wọn, wọ́n gòkè lọ sórí òkè náà, láìjẹ́ pé àpótí ẹ̀rí Olúwa tàbí Mose kúrò nínú ibùdó.
45 Eka jo-Amalek kod jo-Kanaan mane odak e piny got nolor mwalo mi omonjogi kendo neginegogi duto ma gichopo nyaka Horma.
Àwọn ará Amaleki àti àwọn ará Kenaani tó ń gbé lórí òkè sọ̀kalẹ̀ tọ̀ wọ́n, wọ́n bá wọn jà, wọ́n sì lé wọn títí dé Horma.

< Kwan 14 >