< Ayub 31 >

1 “Ne atimo singruok gi wangʼa mondo kik arang nyako moro gi wangʼa mi agombi.
“Mo ti bá ojú mi dá májẹ̀mú, èmi yó ha ṣe tẹjúmọ́ wúńdíá?
2 En kony mane ma dhano yudo kuom Nyasaye man malo, girkeni mane ma Jehova Nyasaye Maratego man malo miye?
Nítorí pé kí ni ìpín Ọlọ́run láti ọ̀run wá? Tàbí kí ni ogún Olódùmarè láti òkè ọ̀run wá.
3 Donge kethruok en mar joma timbegi mono, kendo masira mar joricho?
Kò ṣe pé àwọn ènìyàn búburú ni ìparun wà fún, àti àjàkálẹ̀-ààrùn fún àwọn oníṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀?
4 Donge oneno yorena kendo okwano okangena?
Òun kò ha ri ipa ọ̀nà mi, òun kò ha sì ka gbogbo ìṣísẹ̀ mi?
5 “Kapo ni asewuotho e yor miriambo kata ka tienda osereto kadhi wuondo ngʼato,
“Bí ó bá ṣe pé èmi bá fi àìṣòótọ́ rìn, tàbí tí ẹsẹ̀ mi sì yára sí ẹ̀tàn,
6 to Nyasaye mondo opima e ratil madier kendo obiro yudo ni aonge ketho,
(jẹ́ kí Ọlọ́run wọ́n mí nínú ìwọ̀n òdodo, kí Ọlọ́run le mọ ìdúró ṣinṣin mi.)
7 kendo kapo ni tienda osebaro moweyo yo, kata wengena osewuondo chunya, kata ka gimoro osechido lwetena,
Bí ẹsẹ̀ mí bá yà kúrò lójú ọ̀nà, tí àyà mí sì tẹ̀lé ipa ojú mi, tàbí bí àbàwọ́n kan bá sì lẹ̀ mọ́ mi ní ọwọ́,
8 to kara joma moko ema ocham gik mochiek e puotha, kendo chamba mondo opudh oko.
ǹjẹ́ kí èmi kí ó gbìn kí ẹlòmíràn kí ó sì mújẹ, àní kí a fa irú-ọmọ mi tu.
9 “Kapo ni chunya osegombo dhako moro, kata kapo ni asebuto karito chi ngʼato,
“Bí àyà mi bá di fífà sí ipasẹ̀ obìnrin kan, tàbí bí mo bá lọ í ba de ènìyàn ní ẹnu-ọ̀nà ilé aládùúgbò mi,
10 to kara chiega otine dichwo machielo, kendo chwo mamoko oterre kode.
kí àyà mi kí ó lọ ọlọ fún ẹlòmíràn, kí àwọn ẹlòmíràn kí ó tẹ̀ ara wọn ní ara rẹ̀.
11 Nikech mano en tim wichkuot maduongʼ kendo en richo marach manyaka kum,
Nítorí pé yóò jẹ́ ohun ìtìjú àní, ẹ̀ṣẹ̀ tí a ó ṣe onídàájọ́ rẹ̀.
12 nimar ochalo mach marach mawengʼo manyalo tieko giga duto ma an-go.
Nítorí pé iná ní èyí tí ó jó dé ibi ìparun, tí ìbá sì fa gbòǹgbò ohun ìbísí mi gbogbo tu.
13 “Kapo ni asetamo jotichna machwo gi mamon e adieragi kane gin koda gi wach,
“Tí mo bá sì ṣe àìka ọ̀ràn ìránṣẹ́kùnrin mi tàbí ìránṣẹ́bìnrin mi sí, nígbà tí wọ́n bá ń bá mi jà;
14 to angʼo ma datim ka Nyasaye ochoma tir? En angʼo ma dadwoki ka Nyasaye obiro yala?
kí ni èmi ó ha ṣe nígbà tí Ọlọ́run bá dìde? Nígbà tí ó bá sì ṣe ìbẹ̀wò, ohùn kí ni èmi ó dá?
15 Donge Jal mane ochweya e ich ema nochweyogi bende? Donge en onogo ema ne ochweyowa duto ei minewa?
Ẹni tí ó dá mi ní inú kọ́ ni ó dá a? Ẹnìkan náà kí ó mọ wá ní inú ìyá wa?
16 “Kapo ni asetuono jodhier gik magidwaro kata asemiyo wangʼ dhako ma chwore otho chandruok ojonyo,
“Bí mo bá fa ọwọ́ sẹ́yìn fún ìfẹ́ inú tálákà, tàbí bí mo bá sì mú kí ojú opó rẹ̀wẹ̀sì,
17 kata kapo ni asechamo kuona kenda, ma ok apoge ne nyithind kiye,
tàbí tí mo bá nìkan bu òkèlè mi jẹ, tí aláìní baba kò jẹ nínú rẹ̀;
18 to nyaka aa e tin-na asekonyo nyithind kiye mana kaka akonyo nyithinda awuon, kendo chakre tin-na asebedo ka atayo mon ma chwogi otho.
nítorí pé láti ìgbà èwe mi wá ni a ti tọ́ ọ dàgbà pẹ̀lú mi bí ẹni pé baba, èmi sì ń ṣe ìtọ́jú opó láti inú ìyá mi wá:
19 Kapo ni ne aneno ngʼato angʼata ka koyo nego, kata ka jachan moro onge gi law,
bí èmi bá rí olùpọ́njú láìní aṣọ, tàbí tálákà kan láìní ìbora;
20 to donge ne ogwedha gi chunye nikech ne atwangʼone lewni maliet gi yie rombena.
bí ọkàn rẹ̀ kò bá súre fún mi, tàbí bí ara rẹ̀ kò sì gbóná nípasẹ̀ irun àgùntàn mi;
21 Kapo ni asesando nyithind kiye moko, nikech an gi teko kama ingʼadoe bura,
bí mo bá sì gbé ọwọ́ mi sókè sí aláìní baba, nítorí pé mo rí ìrànlọ́wọ́ mi ní ẹnu ibodè,
22 to kara bada ochodi olwar piny oa e goka, kendo mad ochodi olwar piny koa kama ochomoree.
ǹjẹ́, ní apá mi kí o wọ́n kúrò ní ihò èjìká rẹ̀, kí apá mi kí ó sì ṣẹ́ láti egungun rẹ̀ wá.
23 Nikech ne aluoro kethruok ma Nyasaye nyalo kelona nikech luoro mane aluorogo duongʼne, omiyo ne ok anyal timo gik ma kamago.
Nítorí pé ìparun láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá ni ẹ̀rù ńlá fún mi, àti nítorí ọláńlá rẹ̀ èmi kò le è dúró.
24 “Kapo ni aseketo genona e dhahabu kata asewachone dhahabu maler ni in e kar pondona,
“Bí ó bá ṣe pé mo fi wúrà ṣe ìgbẹ́kẹ̀lé mi, tàbí tí mo bá wí fún fàdákà dídára pé, ‘Ìwọ ni ààbò mi,’
25 kata kapo ni chunya osetingʼore nikech mwandu mangʼeny ma an-go, kata ka asemor kuom mwandu mathoth ma lweta osechoko,
bí mo bá yọ̀ nítorí ọrọ̀ mí pọ̀, àti nítorí ọwọ́ mi dara lọ́pọ̀lọ́pọ̀,
26 kapo ni ne achomo wangʼa e ler mar wangʼ chiengʼ kata ka dwe ringo e tekone mos,
bí mo bá bojú wo oòrùn nígbà tí ń ràn, tàbí òṣùpá tí ń ràn nínú ìtànmọ́lẹ̀,
27 mi dipo chunya nogombo lingʼ-lingʼ kendo ne atingʼonegi bada ka agombo lamogi,
bí a bá tàn ọkàn mi jẹ láti fi ẹnu mi kò ọwọ́ mi,
28 to mago bende gin richo manyaka bi kum, nikech ginyiso ni ok asebedo ja-ratiro ne Nyasaye man malo.
èyí pẹ̀lú ni ẹ̀ṣẹ̀ ti àwọn onídàájọ́ ní láti bẹ̀wò, nítorí pé èmí yóò jẹ́ aláìṣòótọ́ sí Ọlọ́run tí ó wà lókè.
29 “Kapo ni asebedo mamor ka jasika ni e chandruok kata ka asenyiere ka masira obirone,
“Bí ó bá ṣe pé mo yọ̀ sì ìparun ẹni tí ó kórìíra mi. Tàbí bí mo bá sì gbéraga sókè, nígbà tí ibi bá a.
30 to chutho pod ok ayiene dhoga mondo otim richo ka aluongo kwongʼ e ngimane.
Bẹ́ẹ̀ èmi kò sì jẹ ki ẹnu mi ki ó ṣẹ̀ nípa fífẹ́ ègún sí ọkàn rẹ̀.
31 Kapo ni jooda ne pok owacho nyaka nene ni, ‘Ere ngʼama pok Ayub omiyo chiemo moyiengʼ?’
Bí àwọn ènìyàn inú àgọ́ mi kò bá lè wí pé, ‘Ta ni kò ì tí ì jẹ ẹran rẹ̀ ní àjẹyó?’
32 to adier, onge ngʼama wendo mosenindo oko e laru, nikech dho oda nosiko koyaw ne jawuoth.
Àlejò kò wọ̀ ni ìgboro rí; èmí ṣí ìlẹ̀kùn mi sílẹ̀ fún èrò.
33 Kapo ni asepando richona kaka dhano ohero timoga, kata ka akuot gi kethona e chunya,
Bí mo bá bò ẹ̀ṣẹ̀ mi mọ́lẹ̀ bí Adamu ni pápá, ẹ̀bi mi pamọ́ ni àyà mi.
34 nikech ne aluoro ogandana ahinya kendo ne aluor ni anywolana ne nyalo sin koda mine alingʼ, kendo ne ok anyal wuok oko.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni mo ha bẹ̀rù bí? Tàbí ẹ̀gàn àwọn ìdílé ní ń bà mí ní ẹ̀rù? Tí mo fi pa ẹnu mọ́, tí èmí kò sì fi sọ̀rọ̀ jáde?
35 “Yaye, mad dine ngʼato bedie manyalo winja, nikech koro e akwongʼora ni weche ma awachogi gin adier mondo Jehova Nyasaye Maratego obed janeno mara; to ka ok kamano, to ngʼat modonjona oket wechegego e ndiko.
(“Ìbá ṣe pé ẹnìkan le gbọ́ ti èmí! Kíyèsi i, àmì mi, kí Olódùmarè kí ó dá mi lóhùn, kí èmí kí ó sì rí ìwé náà tí olùfisùn mi ti kọ.
36 Adier, dine arwake e goka, dine asidhe ka osimbo.
Nítòótọ́ èmí ìbá gbé le èjìká mi, èmi ìbá sì dé bí adé mọ́ orí mi.
37 Dine anyise sigand ngimana kaka chalo; kendo dine adhi e nyime kaka ruoth.
Èmi ìbá sì sọ iye ìṣísẹ̀ mi fún un, bí ọmọ-aládé ni èmi ìbá súnmọ́ ọ̀dọ̀ rẹ̀.)
38 “Kapo ni asemayo ngʼato puothe mi apuro,
“Bí ilẹ̀ mi bá sì ké rara lòdì sí mi tí a sì fi omijé kún gbogbo poro rẹ̀.
39 kata kapo ni asechamo cham monyakie puothe ka ok achulo, to eka jopur mane opure to kech nego,
Bí mo bá jẹ èso oko mi láìsan owó tàbí tí mo sì mú ọkàn olúwa rẹ̀ fò lọ,
40 to ber mondo kuthe odongi kar ngano kendo buya odongi e puothano kar shairi.” Weche Ayub orumo gi ka.
kí ẹ̀gún òṣùṣú kí ó hù dípò alikama, àti èpò búburú dípò ọkà barle.” Ọ̀rọ̀ Jobu parí.

< Ayub 31 >