< Ayub 29 >

1 Ayub nomedo wuoyo kawacho niya,
Pẹ̀lúpẹ̀lú, Jobu sì tún tẹ̀síwájú nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀, ó sì wí pé,
2 “Yaye, mad ngʼato dwoka e ndalona machon kendo kinde mane Nyasaye orita maber,
“Háà! ìbá ṣe pé èmi wà bí ìgbà oṣù tí ó kọjá, bí ọjọ́ tí Ọlọ́run pa mí mọ́,
3 ka en koda kuonde duto kendo ka lerne ne menyona kuonde motimo mudho mane awuothe!
nígbà tí fìtílà rẹ tàn sí mi ní orí, àti nípa ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ èmi rìn nínú òkùnkùn já.
4 Ee, mano kaka agombo ndalogo mane pod ategno, kinde mane Nyasaye gwedho oda nikech ne en osiepna,
Bí mo ti rí nígbà ọ̀dọ́ mi, nígbà tí ọ̀rẹ́ Ọlọ́run tímọ́tímọ́ bùkún ilé mi,
5 ma en ndalono ma Jehova Nyasaye Maratego ne pod ni koda kendo nyithinda noketa diere,
nígbà tí Olódùmarè wà pẹ̀lú mi, nígbà tí àwọn ọmọ mi wà yí mi ká;
6 ne en ndalo ma yorega ne dhi maber kendo yiende mag zeituni ne nyak maber.
nígbà tí èmi fi òrí-àmọ́ n wẹ ìṣísẹ̀ mi, àti tí àpáta ń tú ìṣàn òróró jáde fún mi wá.
7 “Kindeno kane adonjo gie ranga dala mi abet e koma ei paw bura,
“Nígbà tí mo jáde la àárín ìlú lọ sí ẹnu ibodè, nígbà tí mo tẹ́ ìtẹ́ mi ní ìgboro,
8 to yawuowi ne weyona yo ka onena to jodongo to ne oana malo.
nígbà náà ni àwọn ọmọkùnrin rí mi, wọ́n sì sá pamọ́, àwọn àgbà dìde dúró ní ẹsẹ̀ wọn,
9 Jotend ogendini ne weyo wuoyo, kendo negilingʼ thi ka giumo dhogi.
àwọn ọmọ-aládé dákẹ́ ọ̀rọ̀ sísọ, wọn a sì fi ọwọ́ wọn lé ẹnu.
10 Ruodhi kane onena to ne wuoyo gi dwol mapiny kendo onge ngʼama ne nyalo winjo gima negiwacho.
Àwọn ọlọ́lá dákẹ́, ahọ́n wọn sì lẹ̀ mọ́ èrìgì ẹnu wọn.
11 Ngʼato angʼata mane owinja ne loso maber kuoma, kendo joma nonena ne pwoya,
Nígbà tí etí gbọ́, ó sì súre fún mi, àti nígbà tí ojú sì rí mi, ó jẹ́rìí mi,
12 nikech ne akonyo joma odhier mane ywak ka dwaro kony, kod joma onge wuonegi mane onge gi joma dikonygi.
nítorí mo gbà tálákà tí n fẹ́ ìrànlọ́wọ́, àti aláìní baba tí kò sí olùrànlọ́wọ́ fún un.
13 Ngʼama ne chiegni tho nogwedha; kendo namiyo chuny dhako ma chwore otho duogo mi ower gi mor.
Ẹni tí ó ń kìlọ̀ súre fún mi, èmi sì mú àyà opó kọrin fún ayọ̀.
14 Arwako tim makare kod adiera ka lepa.
Èmi sì mú òdodo wọ̀ bí aṣọ, ẹ̀tọ́ mi dàbí aṣọ ìgúnwà àti adé ọba.
15 Ne abedo wangʼ muofni kendo tiende pudhe.
Mo ṣe ojú fún afọ́jú mo sì ṣe ẹsẹ̀ fún amúnkùn ún.
16 Ne abedo wuon jochan; kendo ne akawo chandruok joma welo.
Mo ṣe baba fún tálákà; mo ṣe ìwádìí ọ̀ràn àjèjì tí èmi kò mọ̀ rí.
17 Ne aketho teko mar joma thiro ji mi agologi e lwet joma dwaro hinyogi.
Mo sì ká eyín ẹ̀rẹ̀kẹ́ ènìyàn búburú, mo sì já ohun ọdẹ náà kúrò ní eyín rẹ̀.
18 “Ne aparo e chunya ni, ‘Tho biro kawa mos ka adak maber e dalana, kendo ka hika mae pinyni oniangʼ,
“Nígbà náà ni mo rò pé, ‘Èmi yóò kú nínú ilé mi, èmi yóò sì mú ọjọ́ mi pọ̀ sí i bí iyanrìn.
19 Achalo gi yath, madongo e bath aora madongo ka ngʼich nikech tiendene ochwo pi kendo thoo biro bedo e bedena gotieno.
Gbòǹgbò mi yóò ta kan omi, ìrì yóò sì sẹ̀ ní gbogbo òru sí ara ẹ̀ka mi.
20 Huma mara biro siko kalandore kendo tekra nosiki!’
Ògo mi yóò wà ní ọ̀tún ní ọ̀dọ̀ mi, ọrun mi sì padà di tuntun ní ọwọ́ mi.’
21 “Ji ne chikona itgi ka geno konyruok mathoth, negirito rieko mawuok e dhoga ka gilingʼ mos.
“Èmi ni ènìyàn ń dẹtí sílẹ̀ sí, wọn a sì dúró, wọn a sì dákẹ́ rọ́rọ́ ní ìmọ̀ràn mi.
22 Onge ngʼama ne loso bangʼa; wechena ne lwar e itgi mos ka ngʼidho.
Lẹ́yìn ọ̀rọ̀ mi, wọn kò tún sọ̀rọ̀ mọ́; ọ̀rọ̀ mi wọ̀ wọ́n ní etí ṣinṣin.
23 Ne girita ka joma rito koth ndalo oro, kendo negimor gi wechena mana ka joma rito kodh chwiri.
Wọn a sì dúró dè mí bí ẹni wí pé wọ́n dúró fún ọ̀wọ́ òjò; wọn a sì mu nínú ọ̀rọ̀ mi bí ẹní mu nínú òjò àrọ̀kúrò.
24 Kane abwonjo kodgi to ne amako dhogi; kendo ler mane rieny koa e lela wangʼa, ne morogi ahinya.
Èmi sì rẹ́rìn-ín sí wọn nígbà tí wọn kò bá gbà á gbọ́; ìmọ́lẹ̀ ojú mi jẹ́ iyebíye sí wọn.
25 An ema ne anyisogi yo monego gilu kendo nabedo kaka ruodhgi; ne achalo ruoth e dier jokedo mage; bende ne achalo ngʼat mahoyo joma ywak.”
Mo la ọ̀nà sílẹ̀ fún wọn, mo sì jókòó bí olóyè wọn. Mo jókòó bí ọba ní àárín ológun rẹ, mo sì rí bí ẹni tí ń tu ẹni tí ń ṣọ̀fọ̀ nínú.

< Ayub 29 >